Pular para o conteúdo
Publicidade

Lefitiku 27

Ìràpadà ohun ó jẹ́ ti Olúwa

1 Olúwa sọ fún Mose . 2 "Sọ fún àwọn ọmọ Israẹli , ẹnìkan jẹ́ ̀jẹ́ pàtàkì láti ya ènìyàn kan sọ́tọ̀ fún Olúwa nípa sísan iye ó , 3 iye owó ọkùnrin láti ọmọ ogún ọdún ọgọ́ta ọdún jẹ́ àádọ́ta òsùwọ̀n ṣékélì fàdákà, gẹ́gẹ́ òsùwọ̀n ṣékélì ti ibi mímọ́ Olúwa. 4 ẹni náà jẹ obìnrin, iye owó rẹ̀ jẹ́ ọgbọ̀n òsùwọ̀n ṣékélì. 5 ẹni náà jẹ́ ọmọ ọdún márùn-ún ogún ọdún, iye owó rẹ̀ jẹ́ ogún ṣékélì fún ọkùnrin àti òsùwọ̀n ṣékélì mẹ́wàá fún obìnrin. 6 ẹni náà jẹ́ ọmọ oṣù kan ọdún márùn-ún, iye owó rẹ̀ jẹ́ òsùwọ̀n ṣékélì fàdákà márùn-ún fún ọkùnrin àti òsùwọ̀n ṣékélì fàdákà mẹ́ta fún obìnrin. 7 ẹni náà jẹ́ ọmọ ọgọ́ta ọdún àti bẹ́̀ lọ, iye owó rẹ̀ jẹ́ òsùwọ̀n ṣékélì mẹ́̀́dógún fún ọkùnrin àti òsùwọ̀n ṣékélì mẹ́wàá fún obìnrin. 8 ẹnìkan ó jẹ́ ̀jẹ́ tálákà púpọ̀ bi san iye owó náà, a ẹni náà síwájú àlùfáà, àlùfáà yóò iye owó ó san e gẹ́gẹ́ agbára ẹni náà ó jẹ́ ̀jẹ́.

9 " ̀jẹ́ ó jẹ́ jẹ́ ẹranko èyí ó jẹ́ ìtẹ́wọ́gbà gẹ́gẹ́ ọrẹ fún Olúwa, irú ẹran bẹ́̀ a fi fún Olúwa di mímọ́. 10 Ẹni ó jẹ́ ̀jẹ́ náà gbọdọ̀ pàrọ̀ ẹran mìíràn, yálà ó pàrọ̀ èyí ó dára èyí dára tàbí èyí dára èyí ó dára. ó ṣe bẹ́̀ ti Olúwa ni ẹranko méjèèjì. 11 Ṣùgbọ́n ó jẹ́ ̀jẹ́ ti ẹranko àìmọ́ a fi tọrẹ: èyí jẹ́ ìtẹ́wọ́gbà i ọrẹ fún Olúwa. ọkùnrin náà ọrẹ náà lọ fún àlùfáà. 12 àlùfáà díye e, gẹ́gẹ́ ó ti dára tàbí ó ti bàjẹ́ . Iye owó náà ni ó jẹ́. 13 ẹni náà fẹ́ á padà, ó gbọdọ̀ san iye owó rẹ̀ àti ìdá ogún iye owó náà láfikún.

14 " ẹnikẹ́ni ya ilẹ̀ rẹ̀ mímọ́ fún Olúwa: àlùfáà sọ iye yóò san gẹ́gẹ́ ilẹ̀ náà ti dára tàbí bàjẹ́ , iye owó náà ni ó jẹ́. 15 ẹni ó ilé náà mímọ́ fẹ́ á padà. Jẹ́ ó fi ìdámárùn-ún owó ìdíyelé rẹ̀ kún ún, yóò si jẹ́ tirẹ̀.

16 " ẹnìkan ya ara ilẹ̀ ìdílé rẹ̀ mímọ́ fún Olúwa. Iye ó jẹ́ ni wọ́n ṣètò gẹ́gẹ́ iye èso a ó fi gbìn ín. Àádọ́ta ṣékélì fàdákà fún òsùwọ̀n homeri irúgbìn barle. 17 ó ba ṣe ọdún ìdásílẹ̀ ni ó ya ilẹ̀ náà mímọ́. Iye owó wọn sọtẹ́lẹ̀ náà ni o san. 18 ó ya ilẹ̀ náà mímọ́ lẹ́yìn ọdún ìdásílẹ̀ àlùfáà sọ iye owó yóò san fún ọdún tókù ọdún ìdásílẹ̀ mìíràn iye owó ó gbọdọ̀ jẹ yóò dínkù. 19 ẹni ó ya ilẹ̀ mímọ́ fẹ́ á padà, ó san iye owó náà pẹ̀àfikún ìdámárùn-ún. Ilẹ̀ náà yóò di tirẹ̀. 20 ra ilẹ̀ náà padà tàbí ó á fún ẹlòmíràn le è ri padà mọ́. 21 a fi ilẹ̀ náà sílẹ̀ ọdún ìdásílẹ̀ yóò di mímọ́ gẹ́gẹ́ ilẹ̀ a fi fún Olúwa. Yóò di ohun ìní àlùfáà.

22 " ẹnikẹ́ni ya ilẹ̀ ó ti í ṣe ilẹ̀ ìdílé rẹ̀ mímọ́ fún Olúwa. 23 àlùfáà sọ iye ó tọ títí di ọdún ìdásílẹ̀. ọkùnrin náà san iye owó náà ọjọ́ náà gẹ́gẹ́ ohun mímọ́ Olúwa. 24 ọdún ìdásílẹ̀ ilẹ̀ náà yóò padà di ti ẹni ó ni í, lọ́wọ́ ẹni a ti á. 25 Gbogbo iye owó wọ̀nyí gbọdọ̀ ìbámu pẹ̀ṣékélì ibi mímọ́, ogún gera.

26 " ẹni ó gbọdọ̀ ya gbogbo àkọ́ẹran sọ́tọ̀. Èyí jẹ́ ti Olúwa nípasẹ̀ òfin àkọ́: yálà akọ màlúù ni tàbí àgùntàn, ti Olúwa ni. 27 ó jẹ́ ̀kan nínú àwọn ẹran mọ́, nígbà náà ni ó á padà gẹ́gẹ́ ìdíyelé rẹ̀, ó fi ìdámárùn-ún e, tàbí a á padà á gẹ́gẹ́ ìdíyelé rẹ̀.

28 27.28: Nu 18.14. " Ohun a mímọ́ pátápátá láti ọwọ́ ẹnikẹ́ni Olúwa tàbí ẹranko tàbí ilẹ̀ ó jogún, òun gbọdọ̀ á ó á padà. Gbogbo ohun ìyàsọ́tọ̀ bẹ́̀ di mímọ́ jùlọ fún Olúwa.

29 " Ẹni ti sọ́tọ̀ fún pípa, ẹnikẹ́ni gbọdọ̀ á padà, pípa ni pa á.

30 27.30-33: Nu 18.21; De 14.22-29. " Gbogbo ìdámẹ́wàá ilẹ̀ náà yálà èso ilẹ̀ ni, tàbí èso igi, ti Olúwa ni. Mímọ́ ni fún Olúwa. 31 ẹnikẹ́ni fẹ́ ra ìdámẹ́wàá nǹkan rẹ̀ padà, o gbọdọ̀ fi márùn-ún kún un. 32 Gbogbo ìdámẹ́wàá àgbò àti ẹran ̀sìn, àní ìdámẹ́wàá ẹran kọjá lábẹ́ ̀darandaran ó jẹ́ mímọ́ fún Olúwa. 33 Ènìyàn gbọdọ̀ wádìí bóyá ó dára tàbí dára, gbọdọ̀ pààrọ̀ rẹ̀. ó pààrọ̀ rẹ̀: àti èyí ó pààrọ̀ àti èyí ó fi pààrọ̀ ni ó jẹ́ mímọ́. Wọn gbọdọ̀ á padà.’ "

34 Àwọn àṣẹ wọ̀nyí ni Olúwa pa fún Mose fún àwọn ọmọ Israẹli orí òkè Sinai.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também