Pular para o conteúdo
Publicidade

Lefitiku 14

Ìwẹ̀nùmọ́ kúrò nínú ààrùn ̀tẹ̀ awọ ara

1 Olúwa sọ fún Mose , 2 14.2-32: Mt 8.4; Mk 1.44; Lk 5.14; 17.14."Èyí ni àwọn ìlànà fún ẹni ààrùn ̀tẹ̀ àkókò ìwẹ̀nùmọ́ rẹ̀, a un tọ àlùfáà . 3 àlùfáà yẹ̀ ́ ̀yìn ibùdó ara rẹ̀ ti kúrò nínú ààrùn ̀tẹ̀ náà. 4 àlùfáà pàṣẹ a ààyè ẹyẹ mímọ́ méjì, igi kedari, òdòdó àti ̀ka hísópù fún ẹni a fẹ́ wẹ̀mọ́. 5 àlùfáà pàṣẹ wọn pa ̀kan nínú àwọn ẹyẹ náà sórí omi ó mọ́ nínú ìkòkò amọ̀. 6 Lẹ́yìn náà ó ri ààyè ẹyẹ pẹ̀igi kedari, òdòdó àti ̀ka hísópù bọ inú ̀jẹ̀ ẹyẹ a ti pa sínú omi náà. 7 Ìgbà méje ni o wọ́n omi yìí ara ẹni a fẹ́ wẹ̀mọ́ kúrò nínú ààrùn ara náà ó ju ààyè ẹyẹ náà sílẹ̀ ìta gbangba.

8 "Ẹni a fẹ́ wẹ̀mọ́ náà gbọdọ̀ fọ aṣọ rẹ̀, gbogbo irun rẹ̀, ó wẹ̀, lẹ́yìn èyí ó ti di mímọ́. Lẹ́yìn náà ó le sínú ibùdó ṣùgbọ́n ó lẹ́yìn àgọ́ rẹ̀ ọjọ́ méje. 9 ó gbogbo irun rẹ̀ ọjọ́ keje: irun orí rẹ̀, irùngbọ̀n rẹ̀, irun ìpéǹpéjú rẹ̀, àti gbogbo irun rẹ̀ tókù. ó fọ aṣọ rẹ̀, ó wẹ̀, yóò mọ́.

10 "ọjọ́ kẹjọ ó àgbò aláìlábùkù méjì àti abo ̀dọ́-àgùntàn ọlọ́dún kan wọn àlébù , pẹ̀ìdámẹ́wàá nínú mẹ́wàá òsùwọ̀n ìyẹ̀fun à pòpọ̀ mọ́ òróró fún ọrẹ ohun jíjẹ àti òsùwọ̀n lógù òróró kan. 11 Àlùfáà ó é mímọ́, yóò ẹni náà a ó sọ di mímọ́ àti ọrẹ rẹ̀ síwájú Olúwa ẹnu-ọ̀àgọ́ ìpàdé.

12 "àlùfáà ̀kan nínú àwọn àgbò àti lógù òróró ó fi ẹbọ ̀bi. ó wọ́n níwájú Olúwa gẹ́gẹ́ ẹbọ fífì. 13 ó pa àgbò náà ibi mímọ́ níbi wọ́n ti ń pa ẹran ẹbọ ̀ṣẹ̀ àti ọrẹ ẹbọ sísun. ẹbọ ̀ṣẹ̀, ẹbọ ̀bi náà jẹ́ ti àlùfáà: ó jẹ́ mímọ́ jùlọ. 14 àlùfáà nínú ̀jẹ̀ ẹbọ ̀bi náà ó fi etí ̀tún ẹni náà a ó wẹ̀mọ́, ó tún fi àtàǹpàkò ọwọ́ ̀tún rẹ̀ àti orí àtàǹpàkò ẹsẹ̀ ̀tún rẹ̀. 15 Àlùfáà yóò díẹ̀ nínú lógù òróró, yóò á àtẹ́lẹwọ́ òsì ara rẹ̀. 16 Yóò ti ìka ìfábẹ̀̀tún rẹ̀ bọ inú òróró àtẹ́lẹwọ́ rẹ̀, yóò wọ́n díẹ̀ nínú rẹ̀ níwájú Olúwa nígbà méje. 17 Àlùfáà yóò lára òróró ó àtẹ́lẹwọ́ rẹ̀ yóò fi etí ̀tún, àtàǹpàkò ọwọ́ ̀tún àti àtàǹpàkò ẹsẹ̀ ̀tún ẹni à ó wẹ̀mọ́, lórí ̀jẹ̀ ẹbọ ̀bi. 18 Àlùfáà yóò fi òróró ó àtẹ́lẹwọ́ rẹ̀ ra orí ẹni a ó wẹ̀mọ́, yóò ṣe ètùtù fún un níwájú Olúwa.

19 "Àlùfáà yóò ẹbọ ̀ṣẹ̀, yóò ṣe ètùtù fún ẹni a ó wẹ̀ kúrò nínú àìmọ́ rẹ̀, lẹ́yìn náà àlùfáà yóò pa ẹran ọrẹ ẹbọ sísun. 20 àlùfáà ó ẹbọ sísun, àti ẹbọ ohun jíjẹ lórí pẹpẹ, àlùfáà ó ṣe ètùtù fún un, òun yóò di mímọ́.

21 "ẹni náà jẹ́ tálákà le è gbogbo nǹkan wọ̀nyí , ó ̀dọ́ àgbò kan ẹbọ ̀bi, yóò , láti ṣe ètùtù fún un, pẹ̀ìdámẹ́wàá òsùwọ̀n ìyẹ̀fun dídára, a mọ́ òróró fún ọrẹ ohun jíjẹ òsùwọ̀n lógù òróró 22 àti àdàbà méjì tàbí ẹyẹlé méjì èyí agbára rẹ̀ , ̀kan fún ẹbọ ̀ṣẹ̀ àti èkejì fún ẹbọ sísun.

23 "ó wọn ọjọ́ kẹjọ fún ìwẹ̀nùmọ́ rẹ̀ síwájú àlùfáà ẹnu-ọ̀àgọ́ ìpàdé níwájú Olúwa. 24 Àlùfáà náà yóò ̀dọ́-àgùntàn ẹbọ ̀bi pẹ̀lógù òróró yóò wọ́n níwájú Olúwa ẹbọ fífì. 25 ó pa ̀dọ́-àgùntàn ẹbọ ̀bi ó lára ̀jẹ̀ rẹ̀. ó fi etí ̀tún, àtàǹpàkò ọwọ́ ̀tún àti àtàǹpàkò ẹsẹ̀ ̀tún ẹni a ó ṣe ìwẹ̀nùmọ́ fún. 26 Àlùfáà yóò da díẹ̀ lára òróró náà àtẹ́lẹwọ́ òsì ara rẹ̀. 27 Yóò fi ìka ìfábẹ̀̀tún rẹ̀ wọ́n òróró ó àtẹ́lẹwọ́ òsì rẹ̀ nígbà méje níwájú Olúwa. 28 Àlùfáà yóò lára òróró ọwọ́ rẹ̀ etí ̀tún, àtàǹpàkò ọwọ́ ̀tún àti àtàǹpàkò ẹsẹ̀ ̀tún ẹni a ń ṣe ìwẹ̀nùmọ́ fún ibi kan náà wọ́n ta ̀jẹ̀ ẹbọ ̀bi . 29 àlùfáà fi ìyókù nínú òróró ọwọ́ rẹ̀ orí ẹni náà a ń ṣe ìwẹ̀nùmọ́ fún, láti ṣe ètùtù fún un iwájú Olúwa. 30 Lẹ́yìn náà ó fi àdàbà tàbí ọmọ ẹyẹlé ẹbọ níwọ̀n agbára rẹ̀ mọ. 31 ̀kan fún ẹbọ ̀ṣẹ̀ àti èkejì fún ẹbọ sísun pẹ̀ẹbọ ohun jíjẹ, àlùfáà yóò ṣe ètùtù níwájú Olúwa ipò ẹni a fẹ́ wẹ̀mọ́."

32 Òfin nìyí fún ẹnikẹ́ni ó ààrùn ara ó le ran lágbára láti ẹbọ ó yẹ fún ìwẹ̀nùmọ́ a ti fi lélẹ̀.

Ìwẹ̀nùmọ́ kúrò nínú ̀tẹ̀ inú ilé

33 Olúwa sọ fún Mose àti Aaroni . 34 "Nígbà ilẹ̀ Kenaani mo fi fún yín ìní, mo fi ààrùn ̀tẹ̀ sínú ilé kan ilẹ̀ ìní yín. 35 ẹni ó ilé náà lọ sọ fún àlùfáà , Èmi ohun ó jọ ààrùn ̀tẹ̀ ilé mi.36 Àlùfáà yóò pàṣẹ ẹnikẹ́ni tàbí ohunkóhun ṣe nínú ilé náà, ó lọ yẹ ̀tẹ̀ náà , ohunkóhun nínú ilé náà à di àìmọ́. Lẹ́yìn èyí àlùfáà yóò wọlé lọ láti yẹ ilé náà . 37 Yóò yẹ ààrùn náà , ààrùn náà ti lára ògiri ilé náà nípa àmì àwọ̀ ewé tàbí àmì pupa ó jinlẹ̀, ju ara ògiri lọ. 38 Àlùfáà yóò jáde kúrò nínú ilé náà, yóò ti ìlẹ̀kùn ilé náà pa fún ọjọ́ méje. 39 Àlùfáà yóò padà yẹ ilé náà ọjọ́ keje. ààrùn náà ti tàn ara ògiri. 40 Àlùfáà yóò pàṣẹ a yọ àwọn òkúta ààrùn náà ti bàjẹ́ kúrò a wọn dànù ibi a àìmọ́ lẹ́yìn ìlú. 41 Yóò wọ́n ha ògiri inú ilé náà yíká. Gbogbo ohun wọ́n fi rẹ́ ilé náà ó ti ha ni wọ́n dànù ibi a àìmọ́ lẹ́yìn ìlú náà. 42 Òkúta mìíràn ni wọ́n fi dípò àwọn a ti yọ dànù, wọ́n rẹ́ ilé náà pẹ̀àwọn ohun ìrẹ́tuntun.

43 "ààrùn yìí tún farahàn lẹ́yìn a ti yọ àwọn òkúta wọ̀nyí a ti ha ilé náà ti a tún rẹ́ . 44 Àlùfáà yóò tún lọ yẹ̀ ́ ààrùn náà tún gbilẹ̀ i nínú ilé náà: ̀tẹ̀ apanirun ni èyí, ilé náà jẹ́ aláìmọ́. 45 Wíwó ni a o, gbogbo òkúta ilé náà, àwọn igi àti gbogbo ohun a fi rẹ́ ni a jáde nínú ìlú ibi a àìmọ́.

46 "Ẹni ó wọ inú ilé náà lẹ́yìn a ti í, yóò di aláìmọ́ títí ìrọ̀lẹ́. 47 Ẹni ó sùn nínú ilé náà tàbí ó jẹun nínú rẹ̀ gbọdọ̀ fọ aṣọ rẹ̀.

48 "àlùfáà yẹ̀ ́ ààrùn náà gbilẹ̀ mọ́ lẹ́yìn a ti rẹ́ ilé náà: àlùfáà pe ilé náà mímọ́, torí ààrùn náà ti lọ. 49 Láti sọ ilé yìí di mímọ́. Àlùfáà yóò ẹyẹ méjì àti igi kedari òdòdó àti hísópù. 50 Yóò pa ̀kan nínú àwọn ẹyẹ náà sórí omi ó mọ́ nínú ìkòkò amọ̀. 51 ó ri igi kedari, hísópù, òdòdó àti ààyè ẹyẹ náà bọ inú ̀jẹ̀ òkú ẹyẹ àti omi ó mọ́ náà ó fi wọ́n ilẹ̀ náà lẹ́̀méje. 52 Yóò fi ̀jẹ̀ ẹyẹ náà, omi ó mọ́, ààyè ẹyẹ, igi kedari, hísópù àti òdòdó sọ ilé náà di mímọ́. 53 àlùfáà ju ààyè ẹyẹ náà sílẹ̀ lẹ́yìn ìlú. Báyìí ni yóò ṣe ètùtù fún ilé náà. Ilé náà yóò mọ́."

54 Àwọn wọ̀nyí ni ìlànà fún èyíkéyìí ààrùn àwọ̀ ara ó le è ràn , fún làpálàpá, 55 àti fún ̀tẹ̀ nínú aṣọ, àti ti ilé, 56 fún ara wíwú, fún èélá àti ibi ara ó ń dán yàtọ̀. 57 Láti a mọ̀ bóyá nǹkan mọ́ tàbí mọ́.

Ìwọ̀nyí ni àwọn òfin fún ààrùn àwọ̀ ara ó ń ràn àti ̀tẹ̀.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também