Pular para o conteúdo
Publicidade

Lefitiku 11

Oúnjẹ mọ́ àti èyí mọ́

1 Olúwa sọ fún Mose àti Aaroni , 2 11.2-47: De 14.3-21."sọ fún àwọn ara Israẹli , Nínú gbogbo ẹranko ń gbé lórí ilẹ̀, àwọn wọ̀nyí ni le jẹ. 3 Gbogbo ẹranko pátákò ẹsẹ̀ rẹ̀ ó ń jẹ àpọ̀jẹ.

4 " Àwọn mìíràn ń jẹ àpọ̀jẹ nìkan. Àwọn mìíràn jẹ́ pátákò ẹsẹ̀ wọn nìkan ni ó , ìwọ̀nyí ni gbọdọ̀ jẹ fún àpẹẹrẹ ó tilẹ̀ jẹ́ ìbákasẹ ń jẹ àpọ̀jẹ ya pátákò ẹsẹ̀, àìmọ́ ni èyí jẹ́. 5 ó tilẹ̀ jẹ́ gara (ẹranko ó dàbí ehoro ń gbé inú àpáta) ń jẹ àpọ̀jẹ; aláìmọ́ ni èyí jẹ́ fún yín. 6 ó tilẹ̀ jẹ́ ehoro ń jẹ àpọ̀jẹ, ṣùgbọ́n ya pátákò ẹsẹ̀; aláìmọ́ ni èyí jẹ́ fún yín. 7 ó tilẹ̀ jẹ́ ẹlẹ́dẹ̀ ya pátákò ẹsẹ̀ ṣùgbọ́n í jẹ àpọ̀jẹ; aláìmọ́ ni èyí jẹ́ fún yín. 8 ṣe jẹ ẹran wọn, gbọdọ̀ fọwọ́ kan òkú wọn. Àìmọ́ ni wọ́n jẹ́ fún yín.

9 " Nínú gbogbo ohun Ọlọ́run ń gbé inú omi Òkun, àti nínú odò: èyíkéyìí ó lẹbẹ àti ìpẹ́ ni jẹ́. 10 Ṣùgbọ́n nínú gbogbo ̀ń gbé inú òkun àti nínú odò lẹbẹ àti ìpẹ́, yálà nínú gbogbo àwọn ń rákò tàbí láàrín gbogbo àwọn ̀alààyè yòókù ń gbé inú omi àwọn ni kórìíra. 11 Nígbà ti kórìíra wọn gbọdọ̀ jẹ ẹran wọn: gbọdọ̀ kórìíra òkú wọn. 12 Ohunkóhun ń gbé inú omi lẹbẹ àti ìpẹ́ gbọdọ̀ jásí ìríra fún yín.

13 " Àwọn ẹyẹ wọ̀nyí ni gbọdọ̀ kórìíra gbọdọ̀ jẹ wọ́n torí ohun ìríra ni wọ́n: idì, oríṣìíríṣìí igún, 14 àwòdì àti onírúurú àṣá, 15 onírúurú ẹyẹ ìwò, 16 Òwìwí, onírúurú ògòǹgò, onírúurú ̀lúùlú, onírúurú àwòdì, 17 Òwìwí kéékèèké, onírúurú òwìwí, 18 Òwìwí funfun àti òwìwí ilẹ̀ pápá, àti àkàlà, 19 àkọ̀, onírúurú òòdẹ̀, atọ́ka àti àdán.

20 " Gbogbo kòkòrò ń ó ń fi ẹsẹ̀ mẹ́rẹ̀̀rin rìn ni wọ́n jẹ́ ìríra fún yín, 21 irú àwọn kòkòrò oniyẹ̀́ wọn ń fi ẹsẹ̀ mẹ́rẹ̀̀rin rìn le jẹ nìyí, àwọn kòkòrò wọ́n ìṣẹ́po ẹsẹ̀ láti máa fi lórí ilẹ̀. 22 Nínú àwọn wọ̀nyí ni jẹ onírúurú eṣú, onírúurú ìrẹ̀ àti onírúurú tata. 23 Ṣùgbọ́n gbogbo ohun ìyókù ń , ń rákò, ó ẹsẹ̀ mẹ́rin, òun ni ̀yin ó ìríra fún yín.

24 " Nípa àwọn wọ̀nyí ni le fi sọ ara yín di àìmọ́. Ẹnikẹ́ni ó fọwọ́ kan òkú wọn yóò di aláìmọ́ títí ìrọ̀lẹ́. 25 Ẹnikẹ́ni ó gbé òkú wọn gbọdọ̀ fọ aṣọ rẹ̀, yóò jẹ́ aláìmọ́ títí ìrọ̀lẹ́.

26 " Àwọn ẹranko pátákò wọn tan tàbí wọn jẹ àpọ̀jẹ jẹ́ àìmọ́ fún yín. Ẹni ó fọwọ́ kan òkú èyíkéyìí nínú wọn yóò jẹ́ aláìmọ́. 27 Nínú gbogbo ẹranko ń fi ẹsẹ̀ mẹ́rẹ̀̀rin rìn, àwọn ń fi èékánná wọn rìn jẹ́ aláìmọ́ fún yín, ẹni ó fọwọ́ kan òkú wọn yóò jẹ́ aláìmọ́ títí di ìrọ̀lẹ́. 28 Ẹni ó gbé òkú wọn gbọdọ̀ fọ aṣọ rẹ̀, yóò jẹ́ aláìmọ́ títí di ìrọ̀lẹ́. Wọ̀nyí jẹ́ àìmọ́ fún yín.

29 " Nínú gbogbo ẹranko ń rìn lórí ilẹ̀ ìwọ̀nyí ni ó jẹ́ àìmọ́ fún yín: Asé, eku àti oríṣìíríṣìí aláǹgbá, 30 Ọmọnílé, alágẹmọ, aláǹgbá, ìgbín àti ̀. 31 Nínú gbogbo ohun ń rìn lórí ilẹ̀, ìwọ̀nyí jẹ́ àìmọ́ fún yín. Ẹnikẹ́ni ó fọwọ́ kan òkú wọn yóò di aláìmọ́ títí ìrọ̀lẹ́. 32 ̀kan nínú wọn wọ́n bọ́ sórí nǹkan kan, ó ti irú ohun náà wúlò , yóò di aláìmọ́ yálà aṣọ ni a fi ṣe é ni tàbí igi, irun aṣọ tàbí àpò, sọ ́ sínú omi yóò jẹ́ aláìmọ́ títí ìrọ̀lẹ́ lẹ́yìn náà ni yóò di mímọ́. 33 èyíkéyìí nínú wọn bọ́ sínú ìkòkò amọ̀, gbogbo ohun ó nínú rẹ̀ ti di àìmọ́. gbọdọ̀ fọ ìkòkò náà. 34 omi inú ìkòkò náà sórí èyíkéyìí nínú oúnjẹ ̀ ń jẹ oúnjẹ náà di aláìmọ́. Gbogbo ohun mímu a jáde láti inú rẹ̀ di àìmọ́. 35 Gbogbo ohun èyíkéyìí nínú òkú wọn lórí di àìmọ́. Yálà ààrò ni tàbí ìkòkò ìdáná wọn gbọdọ̀ di fífọ́. Wọ́n jẹ́ àìmọ́. gbọdọ̀ wọ́n àìmọ́. 36 òkú wọn bọ́ sínú omi tàbí kànga omi nínú, omi náà di aláìmọ́ ṣùgbọ́n ẹnikẹ́ni ó yọ òkú wọn jáde ó fi ọwọ́ kàn án yóò di aláìmọ́. 37 òkú ẹranko wọ̀nyí bọ́ sórí ohun ̀gbìn fẹ́ gbìn wọ́n jẹ́ mímọ́. 38 Ṣùgbọ́n ti da omi ohun ̀gbìn náà òkú wọn bọ́ orí rẹ̀ àìmọ́ ni èyí fún un yín.

39 " ẹran kan nínú àwọn jẹ, ẹnikẹ́ni ó fọwọ́ kan òkú rẹ̀ yóò di aláìmọ́ títí ìrọ̀lẹ́. 40 Ẹnikẹ́ni ó jẹ èyíkéyìí nínú òkú ẹranko náà gbọdọ̀ fọ aṣọ rẹ̀, yóò di aláìmọ́ títí ìrọ̀lẹ́. Ẹnikẹ́ni ó gbé òkú ẹranko yóò fọ aṣọ rẹ̀ yóò àìmọ́ títí ìrọ̀lẹ́.

41 " Ìríra ni gbogbo ohun ń rìn káàkiri lórí ilẹ̀ jẹ́, gbọdọ̀ jẹ wọ́n. 42 gbọdọ̀ jẹ ohunkóhun ń rìn orí ilẹ̀ yálà ó ń fàyàfà tàbí ó ń fi ẹsẹ̀ mẹ́rẹ̀̀rin rìn, tàbí ó ń fi ̀pọ̀lọpọ̀ ẹsẹ̀ rìn ìríra ni èyí. 43 ̀yin gbọdọ̀ fi ohun kan ń rákò, sọ ara yín di ìríra, bẹ́̀ ni ̀yin gbọdọ̀ fi wọ́n sọ ara yín di aláìmọ́, ̀yin yóò fi ti ipa wọn di eléèérí. 44 11.44-45: Le 19.2; 20.7,26; 1Pt 1.16.Èmi ni Olúwa Ọlọ́run yín, ya ara yín sọ́tọ̀ jẹ́ mímọ́ torí mo jẹ́ mímọ́. ṣe sọ ara yín di àìmọ́ nípasẹ̀ ohunkóhun ń rìn káàkiri lórí ilẹ̀. 45 Èmi ni Olúwa ó yín jáde láti ilẹ̀ Ejibiti láti jẹ́ Ọlọ́run yín torí náà, jẹ́ mímọ́ torí mímọ́ ni èmi.

46 11.46: Nu 5.2,3. " Àwọn wọ̀nyí ni ìlànà fún ẹranko, ẹyẹ, gbogbo ̀alààyè ń gbé inú omi àti àwọn ̀ó ń rìn lórí ilẹ̀. 47 gbọdọ̀ mọ ìyàtọ̀ láàrín àìmọ́ àti mímọ́ láàrín ̀alààyè, le jẹ àti èyí le jẹ.’ "

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também