Pular para o conteúdo
Publicidade

Lefitiku 16

Ọjọ́ ètùtù ìwẹ̀nùmọ́ ̀ṣẹ̀

1 Olúwa sọ fún Mose lẹ́yìn ikú àwọn ọmọ Aaroni méjèèjì wọ́n nígbà wọ́n súnmọ́ Olúwa. 2 16.2,12: Hb 6.19; 9.7,25.Olúwa sọ fún Mose , "Kìlọ̀ fún Aaroni arákùnrin rẹ ó ṣe máa nígbà gbogbo Ibi Mímọ́ Jùlọ ó lẹ́yìn aṣọ títa ibi àpótí ̀àti ìtẹ́ àánú , ó ba à nítorí Èmi ó farahàn nínú ìkùùkuu lórí ìtẹ́ àánú.

3 16.3: Hb 9.7. "Báyìí ni Aaroni yóò ṣe máa Ibi Mímọ́ Jùlọ pẹ̀̀dọ́ akọ màlúù fún ẹbọ ̀ṣẹ̀ àti àgbò fún ẹbọ sísun. 4 Òun yóò wọ aṣọ funfun mímọ́ pẹ̀àwọ̀tẹ́lẹ̀ funfun, yóò fi àmùrè funfun mímọ́ í, yóò fìlà funfun, àwọn aṣọ mímọ́ nìwọ̀nyí. Òun yóò fi omi wẹ̀, ó wọ̀ wọ́n. 5 Òun yóò ọmọ ewúrẹ́ méjì láti ̀dọ̀ gbogbo àgbájọpọ̀ àwọn ọmọ Israẹli láti fi ṣe ẹbọ ̀ṣẹ̀ wọ́n, àti àgbò kan fún ẹbọ sísun.

6 "Aaroni yóò fi akọ màlúù ẹbọ ̀ṣẹ̀ èyí ṣe ti ara rẹ̀ òun yóò ṣe ètùtù fún ara rẹ̀ àti ìdílé rẹ̀. 7 Lẹ́yìn náà yóò ewúrẹ́ méjì náà iwájú Olúwa ibi ìlẹ̀kùn àgọ́ ìpàdé. 8 Aaroni yóò dìbò ti àwọn ewúrẹ́ méjèèjì náà, ìbò àkọ́kọ́ fún ti Olúwa, àti èkejì fún ewúrẹ́ ìpààrọ̀. 9 Aaroni yóò ewúrẹ́ ìbò Olúwa , yóò fi ẹbọ ̀ṣẹ̀. 10 Ṣùgbọ́n ewúrẹ́ ìbò gẹ́gẹ́ ewúrẹ́ ìpààrọ̀ ni a ó láààyè síwájú Olúwa láti fi ṣe ètùtù i àti láti jẹ́ ó lọ lọ́fẹ̀́, aginjù.

Ètùtù fún olórí àlùfáà

11 "Aaroni yóò akọ màlúù fún ẹbọ ̀ṣẹ̀ láti ṣe ètùtù fún ara rẹ̀ àti ìdílé rẹ̀. Yóò pa akọ màlúù náà fún ẹbọ ̀ṣẹ̀ tirẹ̀. 12 Yóò àwo tùràrí ó kún fún èédú a ti sun pẹ̀iná láti orí pẹpẹ síwájú Olúwa: àti ̀kúnwọ́ méjì tùràrí a gún kúnná yóò un ̀yìn aṣọ títa. 13 Yóò fi tùràrí náà orí iná níwájú Olúwa: èéfín tùràrí náà ba à le bo ìtẹ́ àánú ó orí àpótí ̀o ba à . 14 Yóò nínú ̀jẹ̀ ọmọ màlúù náà yóò fi ìka rẹ̀ wọ́n ọn, iwájú ìtẹ́ àánú, yóò fi ìka rẹ̀ wọ́n ọn nígbà méje níwájú ìtẹ́ àánú.

Ètùtù fún àwọn ènìyàn

15 16.15: Hb 9.12. "Nígbà yìí ni yóò pa ewúrẹ́ ẹbọ ̀ṣẹ̀ ó fún àwọn ènìyàn yóò ̀jẹ̀ rẹ̀ ̀yìn aṣọ títa, ó ti ṣe ̀jẹ̀ akọ màlúù náà ni yóò ṣe ti ewúrẹ́ yìí, yóò wọ́n ọn sórí ìtẹ́ ètùtù àti síwájú ìtẹ́ ètùtù. 16 Báyìí ni yóò ṣe ètùtù fún Ibi Mímọ́ Jùlọ nítorí àìmọ́ àwọn ará Israẹli àti nítorí gbogbo ìrékọjá wọn àti ìṣọ̀tẹ̀ wọn nípa ̀ṣẹ̀ wọn gbogbo, bákan náà ni yóò ṣe fún àgọ́ ìpàdé, èyí ó láàrín wọn nínú àìmọ́ wọn. 17 ó ṣe ẹyọ ènìyàn kan nínú àgọ́ ìpàdé nígbà òun wọ Ibi Mímọ́ Jùlọ lọ láti ṣe ètùtù, títí di ìgbà yóò fi jáde lẹ́yìn ó ba ṣe ètùtù fúnra rẹ̀ fún ìdílé rẹ̀ àti fún gbogbo àgbájọpọ̀ Israẹli.

18 "Lẹ́yìn náà òun yóò lọ ibi pẹpẹ ó níwájú Olúwa, yóò ṣe ètùtù fún pẹpẹ náà. Yóò nínú ̀jẹ̀ akọ màlúù àti nínú ̀jẹ̀ ewúrẹ́ náà, yóò fi orí ̀kọ̀̀kan ìwo pẹpẹ náà yíká. 19 Lẹ́yìn náà, òun yóò wọ́n ̀jẹ̀ náà sórí rẹ̀ pẹ̀ìka rẹ̀ nígbà méje láti wẹ̀ ́ mọ́ àti láti sọ ́ mímọ́ kúrò nínú àìmọ́ àwọn ọmọ Israẹli.

20 "Lẹ́yìn ti Aaroni ti parí ṣíṣe ètùtù ti Ibi Mímọ́ Jùlọ, ti àgọ́ ìpàdé àti ti pẹpẹ, òun yóò ààyè ewúrẹ́ . 21 Aaroni yóò gbé ọwọ́ rẹ̀ méjèèjì orí ààyè ewúrẹ́ náà, yóò jẹ́wọ́ gbogbo ìwà búburú àti ìṣọ̀tẹ̀ àwọn ara Israẹli e lórí. Gbogbo ìrékọjá wọn àti ̀ṣẹ̀ wọn ni yóò gbé ka orí ewúrẹ́ náà. Yóò rán an lọ ijù láti ọwọ́ ẹni a yàn fún iṣẹ́ náà. 22 Ewúrẹ́ náà yóò ru gbogbo àìṣedéédéé wọn lọ ilẹ̀ ènìyàn gbé. Òun yóò jọ̀wọ́ ewúrẹ́ náà lọ́wọ́ lọ sínú ijù.

23 16.23: El 44.19. "Aaroni yóò padà ibi àgọ́ ìpàdé, yóò bọ́ aṣọ ̀gbọ̀ wọ̀n-ọn-nì sílẹ̀, ó wọ̀ nígbà ó lọ Ibi Mímọ́ Jùlọ, yóò fi wọ́n sílẹ̀ níbẹ̀. 24 Yóò fi omi wẹ ara rẹ̀ ibi mímọ́ kan, yóò wọ aṣọ rẹ̀ yóò ṣí iwájú, yóò ẹbọ sísun ti ara rẹ̀ àti ẹbọ sísun ti àwọn ènìyàn láti ṣe ètùtù fún ara rẹ̀ àti fún àwọn ènìyàn. 25 Òun yóò sun ọrẹ ẹbọ ̀ṣẹ̀ náà lórí pẹpẹ.

26 "Ẹni ó ewúrẹ́ ìpààrọ̀ náà sílẹ̀ yóò fọ aṣọ rẹ̀, yóò wẹ ara rẹ̀ nínú omi, lẹ́yìn èyí ó ibùdó. 27 16.27: Hb 13.11.̀dọ́ akọ màlúù àti ewúrẹ́ ẹbọ ̀ṣẹ̀ a ti ̀jẹ̀ wọn Ibi Mímọ́ Jùlọ ni a gbe jáde kúrò ibùdó. Awọ wọn ni a ó fi iná sun bákan náà. 28 Ẹni ó sun wọ́n yóò fọ aṣọ rẹ̀, yóò wẹ ara rẹ̀, lẹ́yìn èyí ni ó le wọ ibùdó.

29 16.29-34: Le 23.26-32; Nu 29.7-11. "Èyí ni yóò jẹ́ ìlànà títí láé fún un yín, ọjọ́ kẹwàá oṣù keje ni gbọdọ̀ ṣẹ́ ara yín, ṣe ṣe iṣẹ́ kankan, yálà onílé tàbí àlejò ó ń gbé pẹ̀yín. 30 Torí ọjọ́ yìí ni àlùfáà yóò ṣe ètùtù fún yín láti sọ yín di mímọ́, ̀yin à le mọ́ níwájú Olúwa yín kúrò nínú ̀ṣẹ̀ yín gbogbo. 31 Ọjọ́ yìí yóò jẹ́ ọjọ́ ìsinmi pátápátá fún un yín, ̀yin yóò ṣẹ́ ara yín. Èyí yóò jẹ́ ìlànà títí láé. 32 Àlùfáà náà a ti fi òróró yàn a ti sọ di mímọ́ láti máa ṣe iṣẹ́ ìránṣẹ́ ilé ìsìn ipò baba rẹ̀, òun ni ó ṣe ètùtù, yóò wọ aṣọ funfun gbòò àní aṣọ mímọ́ náà, òun yóò ṣe ètùtù. 33 Yóò ṣe ètùtù fún Ibi Mímọ́ Jùlọ, fún ìpàdé àti fún pẹpẹ, yóò ṣe ètùtù fún àlùfáà àti fún gbogbo àgbájọpọ̀ àwọn ènìyàn náà.

34 "Èyí ni yóò jẹ́ ìlànà ayérayé fún yín: láti máa ṣe ètùtù fún àwọn ará Israẹli fún gbogbo ̀ṣẹ̀ wọn lẹ́̀kan lọ́dún."

Ó ṣe gẹ́gẹ́ Olúwa ti pàṣẹ fún Mose.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também