Pular para o conteúdo
Publicidade

Lefitiku 12

Ìwẹ̀nùmọ́ lẹ́yìn ìbímọ

1 12.1-8: Lk 2.22-24. Olúwa sọ fún Mose , 2 "Sọ fún àwọn ará Israẹli : Obìnrin ó lóyún ó ọmọkùnrin, yóò láìmọ́ fún ọjọ́ méje ìgbà ó ipò àìmọ́ lákokò nǹkan oṣù rẹ̀. 3 12.3: Gẹ 17.12; Lk 2.21.ọjọ́ kẹjọ ni kọ ọmọ náà ilà. 4 Obìnrin náà yóò dúró fún ọjọ́ mẹ́tàlélọ́gbọ̀n láti di mímọ́ kúrò nínú ìsun ̀jẹ̀ rẹ̀. gbọdọ̀ fi ọwọ́ kan ohunkóhun ó jẹ́ mímọ́ tàbí ó lọ ibi mímọ́ Olúwa títí di ọjọ́ ìwẹ̀nùmọ́ rẹ̀ yóò kọjá. 5 ó ṣe obìnrin ni ó , fún ̀sẹ̀ méjì ni obìnrin náà yóò fi ipò àìmọ́, gẹ́gẹ́ àkókò nǹkan oṣù rẹ̀. Ó gbọdọ̀ dúró ọjọ́ mẹ́rìndínláàádọ́rin láti di mímọ́ kúrò nínú ìsun ̀jẹ̀ rẹ̀.

6 " Nígbà ọjọ́ ìwẹ̀nùmọ́ rẹ̀ fún ọmọkùnrin tàbí ọmọbìnrin kọjá ó ̀dọ́-àgùntàn ọlọ́dún kan fún àlùfáà ẹnu-ọ̀àgọ́ ìpàdé fún ẹbọ sísun àti ọmọ ẹyẹlé tàbí àdàbà kan fún ẹbọ ̀ṣẹ̀. 7 Ó gbọdọ̀ fi wọ́n ẹbọ níwájú Olúwa láti ṣe ètùtù fún obìnrin náà lẹ́yìn náà ni yóò di mímọ́ kúrò nínú ìsun ̀jẹ̀ rẹ̀.

" Ìwọ̀nyí ni àwọn ìlànà fún obìnrin ó ọmọkùnrin tàbí ọmọbìnrin. 8 12.8: Lk 2.24.lágbára àti fi àgùntàn ṣe é, ó gbọdọ̀ le àdàbà méjì tàbí ọmọ ẹyẹlé méjì, ̀kan fún ẹbọ ̀ṣẹ̀, àti èkejì fún ẹbọ sísun. Báyìí ni àlùfáà yóò ṣe ètùtù fún un. Òun yóò di mímọ́.’ "

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também