Pular para o conteúdo
Publicidade

Lefitiku 15

Ìsunjáde láti inú ara ti ń sọ ni di aláìmọ́

1 Olúwa sọ fún Mose àti Aaroni , 2 "àwọn ọmọ Israẹli sọ̀rọ̀, fún wọn , ìsunjáde ń jáde lára ọkùnrin kan lójú ara, ìsunjáde náà jẹ́ àìmọ́. 3 Yálà ó ń jáde léraléra tàbí ó dúró, èyí yóò sọ ́ di aláìmọ́. Báyìí ni ìsunjáde rẹ̀ ṣe le è sọ ́ di aláìmọ́:

4 " Gbogbo ibùsùn irú ẹni ó ìsunjáde náà sùn di àìmọ́. 5 ẹnikẹ́ni fi ara kan ibùsùn rẹ̀, ó gbọdọ̀ fọ aṣọ rẹ̀ ó wẹ̀. Yóò ipò àìmọ́ títí ìrọ̀lẹ́. 6 Ẹnikẹ́ni ó jókòó lórí ohunkóhun ọkùnrin ó ìsunjáde jókòó le gbọdọ̀ fọ aṣọ rẹ̀, ó wẹ̀, ó láìmọ́ títí di ìrọ̀lẹ́.

7 " Ẹnikẹ́ni ó fọwọ́ kan ọkùnrin náà ó ìsunjáde gbọdọ̀ fọ aṣọ rẹ̀, ó wẹ̀, yóò di aláìmọ́ títí di ìrọ̀lẹ́.

8 " ẹni ó ìsunjáde tu itọ́ ẹni ó mọ́ lára, ẹni ó mọ́ náà gbọdọ̀ fọ aṣọ rẹ̀ ó wẹ̀, yóò ipò àìmọ́ títí di ìrọ̀lẹ́.

9 " Gàárì ẹranko ẹni náà gùn yóò di àìmọ́. 10 Ẹnikẹ́ni ó fọwọ́ kan ohunkóhun ó lábẹ́ ọkùnrin náà di aláìmọ́ títí di ìrọ̀lẹ́. Ẹnikẹ́ni ó irú nǹkan bẹ́̀ gbọdọ̀ fọ aṣọ rẹ̀, ó wẹ ara rẹ̀. Yóò jẹ́ aláìmọ́ títí di ìrọ̀lẹ́.

11 " Ẹnikẹ́ni ọkùnrin ó ìsunjáde ara rẹ̀ fi ara kàn láìfi omi fọ ọwọ́ rẹ̀, gbọdọ̀ fọ aṣọ rẹ̀ ó wẹ̀. Yóò ipò àìmọ́ títí ìrọ̀lẹ́.

12 " Ìkòkò amọ̀ ọkùnrin náà fọwọ́ kàn ni fọ́, gbogbo ohun èlò igi ó fọwọ́ kàn ni fi omi sàn.

13 " Ẹnikẹ́ni a wẹ̀kúrò nínú ìsunjáde rẹ̀ gbọdọ̀ ka ọjọ́ méje fún àwọn ọjọ́ ìwẹ̀nùmọ́: ó fọ aṣọ rẹ̀, ó fi omi wẹ ara rẹ̀, yóò di mímọ́. 14 ọjọ́ kẹjọ ó àdàbà méjì tàbí ọmọ ẹyẹlé méjì, ó ẹnu-ọ̀àgọ́ ìpàdé níwájú Olúwa, ó wọn fún àlùfáà. 15 àlùfáà fi wọ́n ẹbọ: ̀kan fún ọrẹ ̀ṣẹ̀ àti èkejì fún ọrẹ ẹbọ sísun níwájú Olúwa ipò ọkùnrin náà nítorí ìsunjáde rẹ̀.

16 " nǹkan ọkùnrin kan jáde, ó wẹ gbogbo ara rẹ̀, ó ipò àìmọ́ títí ìrọ̀lẹ́. 17 Yálà àwọ̀ tàbí aṣọ nǹkan ọkùnrin lórí ni fọ̀, yóò ipò àìmọ́ di ìrọ̀lẹ́. 18 ọkùnrin kan obìnrin lòpọ̀ nǹkan ọkùnrin jáde lára rẹ̀. Àwọn méjèèjì gbọdọ̀ fi omi wẹ̀, wọ́n ipò àìmọ́ títí di ìrọ̀lẹ́.

19 " obìnrin ń ṣe nǹkan oṣù rẹ̀, obìnrin yìí àìmọ́ títí di ọjọ́ méje. Ẹnikẹ́ni ó fọwọ́ kàn án yóò ipò àìmọ́ títí ìrọ̀lẹ́.

20 " Gbogbo ohun ó sùn àkókò nǹkan oṣù rẹ̀ di àìmọ́. 21 Ẹnikẹ́ni ó fọwọ́ kan ibùsùn rẹ̀ gbọdọ̀ fọ aṣọ rẹ̀ ó wẹ̀, yóò ipò àìmọ́ títí di ìrọ̀lẹ́. 22 Ẹnikẹ́ni ó fọwọ́ kan ohunkóhun ó jókòó gbọdọ̀ fọ aṣọ rẹ̀, ó wẹ̀, yóò ipò àìmọ́ títí di ìrọ̀lẹ́. 23 Ìbá à ṣe ibùsùn tàbí ohunkóhun ó jókòó . Ẹnikẹ́ni ó fọwọ́ kàn án yóò jẹ́ aláìmọ́ títí di ìrọ̀lẹ́.

24 " ọkùnrin kan a lòpọ̀, nǹkan oṣù rẹ̀ kàn án lára, yóò jẹ́ aláìmọ́ fún ọjọ́ méje, gbogbo ibùsùn ọkùnrin náà sùn yóò jẹ́ aláìmọ́.

25 " obìnrin ìsun ̀jẹ̀ fún ọjọ́ púpọ̀ yálà àkókò nǹkan oṣù rẹ̀ tàbí nǹkan oṣù rẹ̀ kọjá ìgbà ó yẹ. Gbogbo ìgbà ó fi ń ìsun ̀jẹ̀ náà ni yóò fi àìmọ́ gẹ́gẹ́ àkókò nǹkan oṣù rẹ̀. 26 Ibùsùn ó ó sùn gbogbo ìgbà ̀jẹ̀ náà ń yóò jẹ́ àìmọ́ ibùsùn rẹ̀ ṣe jẹ́ àkókò nǹkan oṣù rẹ̀. Gbogbo ohun ó jókòó yóò àìmọ́, gẹ́gẹ́ àkókò nǹkan oṣù rẹ̀. 27 Ẹnikẹ́ni ó fọwọ́ kàn wọ́n yóò àìmọ́. Ó gbọdọ̀ fọ aṣọ rẹ̀, ó wẹ̀ ó àìmọ́ títí di ìrọ̀lẹ́.

28 " Nígbà ó di mímọ́ kúrò nínú ìsun rẹ̀, ó ka ọjọ́ méje lẹ́yìn náà, a ó á mímọ́. 29 ọjọ́ kẹjọ ó àdàbà méjì àti ọmọ ẹyẹlé síwájú àlùfáà ẹnu-ọ̀àgọ́ ìpàdé. 30 àlùfáà fi ̀kan ẹbọ ̀ṣẹ̀ àti èkejì fún ẹbọ sísun. Báyìí ni yóò ṣe ètùtù fún un, níwájú Olúwa fún àìmọ́ ìsun ̀jẹ̀ rẹ̀.

31 " ya ará Israẹli sọ́tọ̀ kúrò nínú ohun ó ń sọ wọ́n di aláìmọ́, wọ́n a nínú àìmọ́ wọn nípa bíba ibùgbé mímọ́ mi jẹ́, èyí ó láàrín wọn.’ "

32 Ìwọ̀nyí ni àwọn òfin fún ọkùnrin ó ni ìsunjáde fún ẹnikẹ́ni a sọ di àìmọ́ nípa ìsunjáde nǹkan ọkùnrin rẹ̀. 33 Fún obìnrin nǹkan oṣù rẹ̀, fún ọkùnrin tàbí obìnrin ó ìsunjáde, àti fún ọkùnrin ó ìbálòpọ̀ pẹ̀obìnrin ó jẹ́ aláìmọ́.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também