Pular para o conteúdo
Publicidade

Hosea 14

Ìwòsàn ń bẹ fún àwọn ronúpìwàdà

1 Yípadà ìwọ Israẹli Olúwa Ọlọ́run rẹ.

̀ṣẹ̀ rẹ fa ìparun rẹ!

2 14.2: Hb 13.15. gba ̀rọ̀ Olúwa gbọ́,

yípadà Olúwa.

sọ fún un ,

"Darí gbogbo ̀ṣẹ̀ wa

o fi oore-ọ̀fẹ́ gbà ,

àwa ó fi ètè wa sán an fún

3 Asiria le gbà ;

a í gorí ẹṣin ogun.

A tún sọ ́ mọ́ láé, Àwọn ni òrìṣà wa

àwọn ohun ó fi ọwọ́ wa ṣe;

nítorí lọ́dọ̀ rẹ ni àwọn aláìní baba ń àánú."

4 "Èmi wo àgàbàgebè wọn sàn,

Èmi ó fẹ́ràn wọn, lọ́fẹ̀́,

nítorí ìbínú mi ti yípadà kúrò lọ́dọ̀ wọn.

5 Èmi o dàbí ìrì Israẹli,

wọn o yọ ìtànná bi ewéko lílì.

Bi kedari ti Lebanoni yóò si ta gbòǹgbò.

6 Àṣẹ̀ṣẹ̀yọ ̀ka rẹ̀ yóò dàgbà,

dídán ẹwà yóò rẹ̀ dànù igi olifi.

Òórùn rẹ yóò dàbí igi kedari ti Lebanoni.

7 Àwọn ènìyàn yóò tún padà gbé lábẹ́ òjijì rẹ̀.

Yóò rúwé bi ọkà.

Yóò yọ ìtànná bi àjàrà,

òórùn rẹ yóò dàbí ti wáìnì Lebanoni.

8 Ìwọ Efraimu, kín tún mo ṣe pẹ̀ère òrìṣà?

Èmi ó a lóhùn, èmi ó ṣe ìtọ́rẹ.

Mo dàbí igi junifa ń fi gbogbo ìgbà tutù,

èso ìwọ ń so si ń láti ̀dọ̀ mi."

9 14.9: Ap 13.10. Ta ni ọlọ́gbọ́n? Òun yóò mòye àwọn nǹkan wọ̀nyí.

Ta a ó mọ̀? Òun yóò ìmọ̀ wọn.

Títọ́ ni ̀Olúwa

àwọn olódodo si ń rìn nínú wọn,

ṣùgbọ́n àwọn ọlọ́tẹ̀ ni yóò kọsẹ̀ nínú wọn.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também