Pular para o conteúdo
Publicidade

Hosea 7

1 nígbà èmi ìbá Israẹli láradá.

̀ṣẹ̀ Efraimu ń farahàn

ìwà búburú Samaria ń hàn síta.

Wọ́n ń ṣe ̀tàn,

àwọn olè ń fọ́ ilé;

àwọn ọlọ́ṣà ń jalè òpópónà;

2 ṣùgbọ́n wọn mọ̀

mo rántí gbogbo ìwà búburú wọn.

̀ṣẹ̀ wọn gbé wọn pátápátá;

wọ́n níwájú mi nígbà gbogbo.

3 "Wọ́n ń inú ọba dùn pẹ̀ìwà búburú wọn,

àti inú ọmọ-aládé dùn pẹ̀irọ́ wọn.

4 Alágbèrè ni gbogbo wọn

wọ́n gbóná ààrò àkàrà

a dáwọ́ kíkoná dúró,

lẹ́yìn ìgbà o ti ìyẹ̀fun tán, títí ìgbà yóò .

5 ọjọ́ àjọ̀dún ọba wa

wáìnì ara ọmọ-aládé gbóná

ó darapọ̀ mọ́ àwọn oníyẹ̀yẹ́.

6 Ọkàn wọn ń gbóná i ààrò

wọ́n tọ̀ ́ lọ pẹ̀rìkíṣí,

ìbínú wọn pa lọ́lọ́ gbogbo òru

ó jáde ̀wọ́-iná òwúrọ̀.

7 Gbogbo wọn gbóná ààrò

wọ́n pa gbogbo olórí wọn run,

gbogbo ọba wọn si ṣubú

ṣí ẹnìkan nínú wọn ó .

8 "Efraimu ti darapọ̀ mọ́ àwọn ènìyàn náà;

Efraimu jẹ́ àkàrà a yípadà.

9 Àwọn àlejò ti jẹ agbára rẹ̀ run

ṣùgbọ́n mọ̀.

Ewú ti orí rẹ̀ káàkiri

bẹ́̀ ni kíyèsi i.

10 Ìgbéraga Israẹli ń jẹ́rìí i

ṣùgbọ́n pẹ̀gbogbo èyí

padà ̀dọ̀ Olúwa

Ọlọ́run, tàbí ó a.

11 "Efraimu dàbí àdàbà

rọrùn láti tànjẹ àti aláìgbọ́n

ń Ejibiti nísinsin yìí

tún ń padà lọ si Asiria.

12 Nígbà wọ́n lọ, èmi ó ta àwọ̀n mi sórí wọn,

Èmi ó wọ́n lulẹ̀ gẹ́gẹ́ ẹyẹ ojú ̀run.

Nígbà mo gbọ́ wọ́n rìn pọ̀,

Èmi ó wọ́n fún iṣẹ́ búburú ọwọ́ wọn.

13 Ègbé fún wọn,

nítorí wọ́n ti kúrò lọ́dọ̀ mi!

Ìparun lórí wọn,

nítorí wọ́n ti ṣọ̀tẹ̀ mi!

Èmi fẹ́ láti wọ́n padà.

Ṣùgbọ́n wọ́n ń parọ́ mọ́ mi.

14 Wọn kégbe láti ọkàn wọn,

ṣùgbọ́n wọ́n ń pohùnréré ẹkún lórí ibùsùn wọn.

Wọ́n ara wọn jọ, nítorí ọkà àti wáìnì

ṣùgbọ́n wọ́n yípadà kúrò ̀dọ̀ mi.

15 Mo kọ́ wọn, mo fún wọn agbára,

síbẹ̀ wọ́n tún ń dìtẹ̀ mọ́ mi.

16 Wọn padà ̀dọ̀ ̀gá-ògo;

wọ́n dàbí ọfà ó ti bàjẹ́.

Àwọn aṣíwájú wọn yóò ti ipa idà ṣubú

nítorí ìrunú ahọ́n wọn.

Torí èyí, wọn ó fi wọ́n ṣe

ẹlẹ́ilẹ̀ Ejibiti.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também