Pular para o conteúdo
Publicidade

Daniẹli 6

Daniẹli nínú ihò kìnnìún

1 Ó dára lójú Dariusi láti yan ọgọ́àwọn baálẹ̀ sórí ìjọba, 2 pẹ̀alákòóso mẹ́ta, Daniẹli jẹ́ ̀kan nínú wọn, àwọn baálẹ̀ máa jẹ́ ààbọ̀ fún wọn, ọba ba à ìpalára. 3 Daniẹli ya ara rẹ̀ sọ́tọ̀ láàrín àwọn alákòóso àti àwọn baálẹ̀ nítorí ̀ó tayọ lára rẹ̀ bi ọba ń gbèrò láti fi ṣe olórí i gbogbo ìjọba. 4 Nítorí èyí, gbogbo àwọn alákòóso àti àwọn baálẹ̀ ń gbèrò láti ̀ṣẹ̀ Daniẹli lọ́rùn nínú ètò ìṣèjọba rẹ̀, ṣùgbọ́n wọn ̀ṣẹ̀ kankan i lọ́rùn, wọn ìwà ìbàjẹ́ kankan ó ṣe, nítorí ó jẹ́ olóòtítọ́ ìwà ìjáfara. 5 Nígbẹ̀yìn ni àwọn ọkùnrin wọ̀nyí sọ , "Àwa ìdí kankan láti ̀ṣẹ̀ Daniẹli lọ́rùn, àfi èyí ó í ṣe pẹ̀òfin Ọlọ́run rẹ̀."

6 Nígbà náà ni àwọn alákòóso àti àwọn baálẹ̀ lọ gẹ́gẹ́ ikọ̀ ̀dọ̀ ọba, wọ́n , "Ìwọ Dariusi ọba, o pẹ́! 7 Àwọn alákòóso ọba, ìjòyè, baálẹ̀, olùdámọ̀ràn, àti àwọn olórí gbìmọ̀ pọ̀ ọba kéde òfin kan ẹnikẹ́ni ó gba àdúrà Ọlọ́run tàbí ènìyàn kankan fún ọgbọ̀n ọjọ́, yàtọ̀ fún ìwọ ọba, a ó ju ẹni náà inú ihò kìnnìún. 8 Nísinsin yìí, ìwọ ọba, gbé òfin yìí jáde, o kọ ́ sínú ìwé a ba à i padà ìbámu pẹ̀òfin àwọn Media àti Persia, èyí le è parẹ́." 9 Nígbà náà, ni Dariusi ọba fi ọwọ́ ìwé àṣẹ náà.

10 Lóòótọ́, Daniẹli mọ̀ a ti fi ọwọ́ ìwé òfin náà, síbẹ̀ ó wọ ilé e rẹ̀ lọ, nínú yàrá òkè, ó ṣí fèrèsé èyí ó kọjú Jerusalẹmu sílẹ̀. Ó kúnlẹ̀ lórí orúnkún un rẹ̀ ̀̀mẹ́ta lójoojúmọ́, ó gbàdúrà, ó fi ọpẹ́ fún Ọlọ́run gẹ́gẹ́ ìṣe rẹ̀ tẹ́lẹ̀. 11 Nígbà náà ni, àwọn ọlọ̀tẹ̀ yìí ara wọn jọ, wọ́n Daniẹli ó ń gba àdúrà, ó ń bẹ̀bẹ̀ fún àánú lọ́dọ̀ Ọlọ́run. 12 Wọ́n lọ iwájú ọba, wọ́n rán ọba létí nípa òfin ó ṣe , "Ìwọ ha fi ọwọ́ òfin ìwọ̀n ọgbọ̀n ọjọ́ ẹnikẹ́ni ó gba àdúrà Ọlọ́run tàbí ènìyàn, láì ṣe ìwọ ọba, a ó gbé e sínú ihò kìnnìún?"

Ọba dáhùn , "Àṣẹ náà dúró síbẹ̀, ìbámu pẹ̀òfin àwọn ará Media àti Persia, èyí a le è parẹ́."

13 Nígbà náà, ni wọ́n sọ fún ọba , "Daniẹli, ̀kan lára ìgbèkùn Juda, ka ìwọ ọba , tàbí àṣẹ ̀ rẹ o fi ọwọ́ . Òun tún ń gba àdúrà ̀̀mẹ́ta lójúmọ́." 14 Nígbà ọba gbọ́ èyí, inú rẹ̀ bàjẹ́ gidigidi; ó pinnu láti Daniẹli yọ, títí oòrùn fi rọ̀, ó sa gbogbo ipá a rẹ̀ láti gba Daniẹli sílẹ̀.

15 Nígbà náà, ni àwọn ọlọ̀tẹ̀ wọ̀nyí ara wọn jọ ̀dọ̀ ọba, wọ́n fún un , "Ìwọ ọba rántí , ìbámu pẹ̀òfin àwọn Media àti Persia àṣẹ tàbí ìkéde ọba ṣe a le è i padà."

16 Nígbà náà, ni ọba pàṣẹ, wọ́n Daniẹli, wọ́n sọ ́ sínú ihò kìnnìún. Ọba sọ fún Daniẹli , "Ọlọ́run rẹ ìwọ ń sìn nígbà gbogbo ó gbà ́!"

17 A gbé òkúta kan , wọ́n fi ẹnu ihò náà, ọba í pa pẹ̀òrùka èdìdì rẹ̀ àti pẹ̀òrùka àwọn ọlọ́rẹ̀, nítorí a ṣe ohunkóhun padà nítorí i Daniẹli. 18 Nígbà náà ni ọba padà ààfin rẹ̀, ó lo gbogbo òru náà láì jẹun, gbọ́ orin kankan, bẹ́̀ ni le è sùn òru ọjọ́ náà.

19 òwúrọ̀ kùtùkùtù, ni ọba dìde ó sáré lọ ibi ihò kìnnìún náà. 20 Nígbà ó súnmọ́ ibi ihò náà ibi Daniẹli , ó pe Daniẹli pẹ̀ìtara , "Daniẹli, ìránṣẹ́ Ọlọ́run alààyè, ṣé Ọlọ́run rẹ ìwọ ń sìn tọ̀sán tòru, gbà ́ lọ́wọ́ kìnnìún ?"

21 Daniẹli dáhùn , "Ọba pẹ́! 22 Ọlọ́run mi rán angẹli i rẹ̀, ó àwọn kìnnìún lẹ́nu. Wọn le è pa lára, nítorí a mi gẹ́gẹ́ aláìlẹ́ṣẹ̀ iwájú rẹ̀. Bẹ́̀ ni èmi hu ìwà ìbàjẹ́ kan níwájú rẹ ìwọ ọba."

23 Inú ọba dùn gidigidi, ó pàṣẹ a Daniẹli jáde láti inú ihò. Nígbà a Daniẹli jáde nínú ihò, ojú ọgbẹ́ kan ara rẹ̀, nítorí ó gbẹ́kẹ̀Ọlọ́run rẹ̀.

24 Ọba pàṣẹ , a àwọn alátakò Daniẹli , a wọ́n inú ihò kìnnìún, pẹ̀ìyàwó àti àwọn ọmọ wọn. wọn ìsàlẹ̀ ihò, kìnnìún lágbára lórí i wọn, wọ́n fọ́ gbogbo egungun wọn.

25 Nígbà náà ni Dariusi ọba kọ̀gbogbo ènìyàn orílẹ̀-èdè, àti gbogbo jákèjádò ilẹ̀ náà:

"ìre yín máa pọ̀ i!

26 "Mo gbé àṣẹ kan jáde , gbogbo agbègbè ìjọba mi, gbogbo ènìyàn gbọdọ̀ bẹ̀, wọn ó bọ̀wọ̀ fún Ọlọ́run Daniẹli.

"Nítorí òun ni Ọlọ́run alààyè.

Ó títí ayé;

ìjọba rẹ̀ le è parun,

ìjọba rẹ̀ ìpẹ̀kun.

27 Ó ń yọ ni, ó ń gbani ;

ó ń ṣe iṣẹ́ àmì àti ìyanu

̀run àti ayé.

Òun gba Daniẹli

kúrò lọ́wọ́ agbára kìnnìún."

28 Daniẹli ṣe rere àkókò ìjọba Dariusi àti àkókò ìjọba Kirusi ti Persia.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também