Pular para o conteúdo
Publicidade

Hosea 8

Israẹli yípadà kúrò ọnà

1 "Fi ìpè ẹnu rẹ!

Ẹyẹ idì lórí ilé Olúwa

nítorí àwọn ènìyàn ti dalẹ̀ májẹ̀,

wọ́n ti ṣọ̀tẹ̀ òfin mi.

2 Israẹli kígbe ,

Ọlọ́run wa, àwa mọ̀ ́n!

3 Ṣùgbọ́n Israẹli ti kọ ohun ó dára sílẹ̀

̀yóò máa lépa rẹ̀.

4 Wọ́n fi àwọn ọba jẹ ṣùgbọ́n, í ṣe nípasẹ̀ mi

wọ́n yan ọmọ-aládé láì si ìmọ̀ mi níbẹ̀.

Wọ́n fi fàdákà àti wúrà

ṣe ère fún ara wọn,

si ìparun ara wọn.

5 Ju ère ẹgbọrọ màlúù rẹ, ìwọ Samaria!

Ìbínú mi ń ru wọn:

yóò ti pẹ́ wọ́n ipò àìmọ̀kan?

6 Israẹli ni wọ́n ti !

Ère yìí agbẹ́gilére ṣe é,

àní ère ẹgbọrọ màlúù Samaria, ni a ó fọ́ túútúú.

7 "Wọ́n gbin afẹ́fẹ́

wọ́n ìjì.

Igi ọkà lórí,

oúnjẹ .

ó tilẹ̀ ọkà

àwọn àjèjì ni yóò jẹ.

8 A ti gbé Israẹli ,

báyìí, ó ti láàrín àwọn orílẹ̀-èdè

ohun èlò wúlò.

9 Nítorí wọ́n ti gòkè lọ Asiria

gẹ́gẹ́ kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ igbó ń rìn kiri.

Efraimu ti ta ara rẹ̀ fún àwọn olólùfẹ́ rẹ̀.

10 ó tilẹ̀ jẹ́ wọ́n ti ta ara wọn àárín Orílẹ̀-èdè,

Èmi ó ṣà wọ́n jọ nísinsin yìí.

Wọn ó bẹ̀rẹ̀ í ṣòfò dànù

lọ́wọ́ ìnilára ọba alágbára.

11 "Nítorí Efraimu ti kọ́ pẹpẹ púpọ̀ fún ìrúbọ ̀ṣẹ̀

gbogbo rẹ̀ ti di pẹpẹ ìdẹ́ṣẹ̀ fún un

12 Mo kọ ̀pọ̀lọpọ̀ ohun ó jẹ́ òfin mi fún wọn,

ṣùgbọ́n wọn á ohun àjèjì.

13 Wọ́n ń ẹbọ wọ́n yàn fún mi,

wọ́n ń jẹ ẹran ibẹ̀,

ṣùgbọ́n inú Olúwa dùn wọn.

Báyìí yóò rántí ìwà búburú wọn

yóò jẹ wọ́n fún ̀ṣẹ̀ wọn.

Wọn yóò padà Ejibiti.

14 8.14: Am 1.4,7,10,12,14; 2.2,5. Nítorí Israẹli ti gbàgbé ẹlẹ́dàá rẹ̀

Ó ń kọ́ ààfin púpọ̀

Juda ti kọ́ ìlú olódi púpọ̀

ṣùgbọ́n èmi ó rán iná kan

orí àwọn ìlú rẹ̀ èyí yóò jẹ ibi agbára rẹ̀ run."

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também