Pular para o conteúdo
Publicidade

Habakuku 1

1 Àsọtẹ́lẹ̀ wòlíì Habakuku .

Ìráhùn Habakuku

2 1.2: Isa 13.1–14.23; 47; Jr 50–51. Olúwa, èmi yóò ti pẹ́ fún ìrànlọ́wọ́,

ṣùgbọ́n ti ìwọ ni fetí mi?

Tàbí kígbe ti, "Ìwà ipá!"

Ṣùgbọ́n ìwọ gbàlà?

3 Èéṣe ìwọ fi mi àìṣedéédéé?

Èéṣe ìwọ fi ààyè gba ìwà ìkà?

Ìparun àti ìwà ipá iwájú mi;

ìjà ń bẹ, ìkọlù pẹ̀.

4 Nítorí náà, òfin di ohun àìkàsí,

ìdájọ́ òdodo borí.

Àwọn ẹni búburú àwọn olódodo ,

nítorí náà ni ìdájọ́ òdodo ṣe padà.

Ìdáhùn Olúwa

5 1.5: Ap 13.41. "wo inú àwọn kèfèrí, ki wòye,

háà ó ṣe yin gidigidi.

Nítorí èmi ó ṣe ohun kan ọjọ́ yín

̀yin jẹ́ gbàgbọ́,

a tilẹ̀ sọ fún yin.

6 1.6: If 20.9. Nítorí , èmi yóò gbé àwọn ara Babeli dìde,

àwọn aláìláàánú àti onínú-fùfù ènìyàn

ó rin gbogbo ilẹ̀ ayé

láti fi agbára gbà àwọn ibùgbé í ṣe tiwọn.

7 Wọn jẹ́ ènìyàn ti a bẹ̀, a páyà,

ìdájọ́ wọn, àti ọláńlá wọn,

yóò máa ti inú wọn jáde.

8 Ẹṣin wọn yára ju ẹkùn lọ,

wọ́n gbóná ìkookò àṣálẹ́ lọ

àwọn ẹlẹ́ṣin wọn yóò tan ara wọn ;

wọn yóò láti ̀jíjìn réré,

wọn yóò ẹyẹ igún ń láti jẹrun,

9 gbogbo wọn fún ìwà ipá

ìwò ojú wọn yóò síwájú;

wọn ko ìgbèkùn jọ iyanrìn.

10 Wọn ó si máa fi àwọn ọba ṣẹ̀sín

wọn ó tún kẹ́gàn àwọn aládé.

Wọn yóò fi gbogbo ìlú odi alágbára rẹ́rìn-ín;

nítorí , wọn yóò ko erùpẹ̀ jọ, wọn yóò gbà á.

11 Nígbà náà ni inú rẹ̀ yóò yípadà,

yóò rékọjá, yóò si ṣẹ̀ kíka agbára rẹ̀ yìí iṣẹ́ òrìṣà rẹ̀."

Ìráhùn lẹ́̀kejì Habakuku

12 Olúwa, ǹjẹ́ láti ayérayé kọ ni ìwọ ?

Olúwa Ọlọ́run mi. Ẹni mímọ́ mi, àwa yóò

Olúwa, ìwọ yàn wọn fún ìdájọ́;

Ọlọ́run alágbára, ìwọ fi ẹsẹ̀ wọn múlẹ̀ fún ìbáwí.

13 Ojú rẹ mọ́ tónítóní láti wo ibi;

ìwọ le gbà ìwà ìkà

nítorí ni ìwọ ṣe gba àwọn alárékérekè láààyè?

Nítorí ni ìwọ ṣe dákẹ́ nígbà ẹni búburú ń pa

ẹni i ṣe olódodo ju wọn lọ run?

14 Ìwọ sọ ènìyàn di ẹja inú Òkun,

ohun ń rákò wọn ko ni alákòóso.

15 Àwọn ènìyàn búburú fi àwọ̀n wọn gbé wọn sókè

ó wọn jọ nínú àwọ̀n ńlá rẹ̀;

nítorí náà, ó dunnú, ó yọ̀ pẹ̀.

16 Nítorí náà, ó ẹbọ àwọ̀n rẹ̀,

ó ń sun tùràrí fún àwọ̀n ńlá rẹ̀

nítorí pẹ̀àwọ̀n rẹ̀ ni ó fi ń gbé ìgbádùn

ó ń gbádùn pẹ̀oúnjẹ ó ú.

17 Ǹjẹ́ wọn yóò ha máa pa àwọ̀n wọn mọ́ òfìfo ,

wọn yóò pa orílẹ̀-èdè run láìsí àánú?

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também

Habacuque
Ver todos os capítulos de Habacuque