Pular para o conteúdo
Publicidade

Nahumu 3

A fi Ninefe

1 Ègbé ni fún ìlú ̀jẹ̀ ,

gbogbo rẹ̀ kún fún èké,

ó kún fún olè,

ìjẹ kúrò!

2 Ariwo pàṣán àti ariwo

kíkùn kẹ̀kẹ́ ogun

àti jíjó ẹṣin

àti gbígbọn kẹ̀kẹ́ ogun jìgìjìgì!

3 Ológun orí ẹṣin ń fi ìgbónára

ju idà wọn mọ̀nàmọ́

̀kọ̀ rẹ̀ ti ń dán yanran òkè!

̀pọ̀lọpọ̀ si àwọn ẹni a pa,

àti ̀pọ̀lọpọ̀ òkú;

òkú ni òpin;

àwọn ènìyàn ń kọsẹ̀ lára àwọn òkú.

4 Nítorí ̀pọ̀lọpọ̀ panṣágà

àgbèrè ó rójú rere gbà,

ìyá àjẹ́ ó ṣọ́ àwọn Orílẹ̀-èdè di ẹrú

nípa àgbèrè rẹ̀

àti àwọn ìdílé nípa ìṣe àjẹ́ rẹ̀.

5 "Èmi dojúkọ ́," ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun .

"Èmi ó si aṣọ àwọ̀tẹ́lẹ̀ rẹ ojú rẹ.

Èmi yóò fi ìhòhò rẹ̀ han àwọn orílẹ̀-èdè

àti ìtìjú rẹ̀ han àwọn ilẹ̀ ọba.

6 Èmi yóò da ̀gbin ó ni ìríra ara,

èmi yóò sọ ́ di aláìmọ́,

èmi yóò sọ ́ di ẹlẹ́.

7 Gbogbo àwọn ó ba ́ yóò káàánú fún , wọn yóò ,

Ninefe ṣòfò, ta ni yóò kẹ́dùn rẹ?

Níbo ni èmi o ti olùtùnú fún ?"

8 Ǹjẹ́ ìwọ ha sàn ju Tebesi lọ,

èyí ó ibi odò Naili,

omi káàkiri?

Odò náà jẹ́ ààbò rẹ̀,

omi si jẹ́ odi rẹ̀.

9 Etiopia àti Ejibiti ni agbára rẹ, òpin;

Puti àti Libia ni àwọn olùgbèjà rẹ̀.

10 Síbẹ̀síbẹ̀ a o ìgbèkùn

o lọ oko ẹrú.

Àwọn ọmọ wẹ́wẹ́ rẹ̀ ni a ó fọ́ mọ́lẹ̀

orí ìta gbogbo ìgboro.

Wọ́n di ìbò nítorí àwọn ọlọ́rẹ̀ ọkùnrin,

gbogbo àwọn ọlọ́rẹ ni a fi ̀wọ̀n .

11 Ìwọ pẹ̀yóò mu àmupara;

a ó fi ́ pamọ́

ìwọ pẹ̀yóò máa ṣe àfẹ́ààbò nítorí ti ̀náà.

12 Gbogbo ilé ìṣọ́ agbára rẹ yóò dàbí igi ̀pọ̀tọ́

pẹ̀àkọ́pọ́n èso wọn;

nígbà wọ́n ń gbọ̀n wọ́n,

̀pọ̀tọ́ yóò bọ́ ẹnu àwọn ̀jẹun.

13 Kíyèsi gbogbo àwọn jagunjagun!

Obìnrin ni gbogbo wọn.

Ojú ibodè rẹ a ó ṣí sílẹ̀ gbagada,

fún àwọn ̀rẹ;

iná yóò ̀ìdábùú ìlẹ̀kùn ibodè rẹ.

14 Pọn omi nítorí ìhámọ́,

ilé ìṣọ́ rẹ lágbára i

wọ inú amọ̀

o tẹ erùpẹ̀,

ó tún ibi a ti ń sun bíríkì-amọ̀ ṣe ó le.

15 Níbẹ̀ ni iná yóò ti ́ run;

idà yóò kúrò,

yóò jẹ ́ i kòkòrò,

yóò sọ ara rẹ̀ di púpọ̀ i tata,

àní, di púpọ̀ eṣú!

16 Ìwọ ti sọ àwọn oníṣòwò rẹ di púpọ̀

títí wọn yóò fi pọ̀ ju ìràwọ̀ ojú ̀run lọ,

ṣùgbọ́n bi eṣú ni wọn yóò sọ ilẹ̀ náà di ahoro, wọn yóò lọ.

17 Àwọn aládé rẹ̀ dàbí eṣú,

àwọn ̀gágun rẹ dàbí ẹlẹ́ǹgà ńlá,

èyí ń sínú ọgbà ni ọjọ́ òtútù,

ṣùgbọ́n nígbà oòrùn jáde, wọ́n sálọ,

ẹnìkan mọ ibi wọ́n gbé .

18 Ìwọ ọba Asiria,

àwọn olùṣọ́-àgùntàn rẹ̀ ń tòògbé;

àwọn ọlọ́rẹ dùbúlẹ̀ láti sinmi.

Àwọn ènìyàn rẹ fọ́nká lórí àwọn òkè ńlá,

ẹnikẹ́ni wọn jọ.

19 ohun ó wo ọgbẹ́ ̀ rẹ sàn;

ọgbẹ́ rẹ kún fún ìrora,

Gbogbo ẹni ó gbọ́ ìròyìn rẹ

yóò pàtẹ́wọ́ lórí,

nítorí ta ni pín nínú

ìwà búburú rẹ ti ti lópin.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também

Naum
Ver todos os capítulos de Naum