Pular para o conteúdo
Publicidade

Nahumu 2

Ìṣubú Ninefe

1 Àwọn apanirun ti dìde , ìwọ Ninefe.

Pa ilé ìṣọ́ mọ́,

ṣọ́ ̀náà,

di àmùrè,

̀gbẹ́ rẹ ó le múra gírí.

2 Olúwa yóò ọláńlá Jakọbu padà sípò

gẹ́gẹ́ ọláńlá Israẹli

ó tilẹ̀ jẹ́ àwọn apanirun ti pa ibẹ̀ run,

wọ́n ba ̀ka àjàrà wọn jẹ́.

3 Asà àwọn ọmọ-ogun rẹ̀ di pupa;

àwọn ológun wọn wọ aṣọ òdòdó.

Idẹ ó lórí kẹ̀kẹ́ ogun ń kọ mọ̀nàmọ́

ọjọ́ a pèsè wọn sílẹ̀ tán;

igi firi ni a ó tìtì.

4 Àwọn kẹ̀kẹ́ ogun yóò ya bo àwọn pópónà,

wọn yóò máa sáré síwá àti sẹ́yìn àárín ìgboro.

Wọn dàbí ètùfù iná;

ó kọ i mọ̀nàmọ́.

5 Ninefe yóò ṣe àṣàrò àwọn ọlọ́rẹ̀;

síbẹ̀ wọ́n ń kọsẹ̀ ojú ̀wọn;

wọn sáré lọ ibi odi rẹ̀,

a ó pèsè ààbò rẹ̀.

6 A ó ṣí ìlẹ̀kùn àwọn odò wọ̀n-ọn-nì sílẹ̀,

a ó ààfin náà di wíwó palẹ̀.

7 A pa á láṣẹ ìlú náà, èyí a ti fi ìdí rẹ̀ múlẹ̀

ni a ó ìgbèkùn lọ.

A ó un gòkè

àti àwọn ìránṣẹ́bìnrin rẹ̀ yóò kérora ti ẹyẹ àdàbà,

wọn a máa lu àyà wọn.

8 Ninefe dàbí adágún omi,

omi rẹ̀ ń gbẹ́ lọ.

"Dúró! Dúró!" ni wọ́n ó máa kígbe,

ṣùgbọ́n ẹnìkankan yóò wo ̀yìn.

9 "ìkógun fàdákà!

ìkógun wúrà!

Ìṣúra wọn ti lópin náà,

àti ọrọ̀ kúrò nínú gbogbo ohun èlò ti a fẹ́!"

10 Òun ti ṣòfò, ó si di asán, ó di ahoro:

ọkàn pami, eékún ń lu ara wọn,

ìrora púpọ̀ nínú gbogbo ẹgbẹ́

àti ojú gbogbo wọ́n rẹ̀wẹ̀.

11 Níbo ni ihò àwọn kìnnìún

àti ibi ìjẹun àwọn ọmọ kìnnìún,

níbi kìnnìún, àní abo kìnnìún ń rìn,

àti ọmọ kìnnìún, láìsí ohun ìbẹ̀.

12 Kìnnìún tipa ̀pọ̀lọpọ̀ fún àwọn ọmọ rẹ̀,

ó fún un ẹran ọdẹ ọrùn pa fún àwọn abo kìnnìún rẹ̀,

ó fi ohun pípa kún ibùgbé rẹ̀

àti ihò rẹ̀ fún ohun ọdẹ.

13 "Kíyèsi i èmi dojúkọ ́,"

ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun .

"Èmi yóò fi kẹ̀kẹ́ rẹ̀ wọ̀n-ọn-nì jóná nínú èéfín,

idà yóò jẹ ọmọ kìnnìún rẹ̀ wọ̀n-ọn-nì run.

Èmi yóò ohun ọdẹ rẹ kúrò lórí ilẹ̀ ayé.

Ohùn àwọn ìránṣẹ́ rẹ

ni a yóò tún gbọ́ mọ́."

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também

Naum
Ver todos os capítulos de Naum