Pular para o conteúdo
Publicidade

Nahumu 1

1 ̀rọ̀-ìmọ̀ nípa Ninefe. Ìwé ìran Nahumu ará Elkoṣi.

Ìbínú Olúwa Ninefe

2 Ọlọ́run ń jẹ owú, ó ń gbẹ̀san,

Olúwa ń gbẹ̀san, ó kún fún ìbínú.

Olúwa ń gbẹ̀san lára àwọn ̀rẹ̀.

Ìbínú rẹ̀ padà lórí àwọn ̀rẹ̀.

3 1.3: Isa 10.5-34; Sf 2.12-15. Olúwa lọ́ra láti bínú, ó tóbi agbára;

Olúwa yóò fi àwọn ẹlẹ́ṣẹ̀ sílẹ̀ láìjìyà.

̀rẹ̀ nínú afẹ́fẹ́ àti nínú ìjì,

ìkùùkuu sánmọ̀ ni eruku ẹsẹ̀ rẹ̀.

4 Ó òkun , ó ó gbẹ;

Ó sìsọ gbogbo odò di gbígbẹ.

Baṣani àti Karmeli rọ.

Ìtànná Lebanoni rẹ̀ sílẹ̀.

5 Àwọn òkè ńlá wárìrì níwájú rẹ̀,

àwọn òkè kéékèèké di yíyọ́,

ilẹ̀ ayé jóná níwájú rẹ̀,

àní ayé àti gbogbo àwọn ń gbé inú rẹ̀.

6 Ta ni ó dúró níwájú ìbínú rẹ̀?

Ta ni ó faradà gbígbóná ìbínú rẹ̀?

Ìbínú rẹ̀ jáde iná;

àwọn àpáta fọ́ túútúú níwájú rẹ̀.

7 Rere ni Olúwa,

òun ni ààbò ọjọ́ ìpọ́njú.

Òun tọ́àwọn ó gbẹ́kẹ̀e,

8 ṣùgbọ́n pẹ̀ìkún omi ńlá

òun yóò fi ṣe ìparun láti ibẹ̀ òpin;

òkùnkùn yóò máa lépa àwọn ̀rẹ̀.

9 ni ̀yìn ń gbìmọ̀ lòdì Olúwa?

Òun yóò fi òpin i,

ìpọ́njú yóò wáyé ìgbà kejì.

10 Wọn yóò lọ́papọ̀ ̀gún òṣùṣú

wọn yóò mu àmupara nínú ọtí wáìnì wọn

a ó run wọn gẹ́gẹ́ bi àgékù koríko gbígbẹ.

11 Láti ̀dọ̀ rẹ, ìwọ Ninefe, ni ẹnìkan ti jáde

ó ń gbèrò ibi Olúwa

ti ó ń gbìmọ̀ búburú.

12 Báyìí ni Olúwa :

"wọ́n tilẹ̀ ni ìfọwọ́sowọ́pọ̀, wọ́n pọ̀ níye,

ṣùgbọ́n, báyìí a ó wọn lulẹ̀,

nígbà òun ó kọjá.

mo tilẹ̀ ti pọ́n lójú ìwọ Juda, èmi yóò pọ́n lójúmọ́.

13 Nísinsin yìí ni èmi yóò àjàgà wọn kúrò ọrùn rẹ

èmi yóò ṣẹ́kẹ́ṣẹkẹ̀ rẹ dànù."

14 Olúwa ti fi àṣẹ kan lélẹ̀ nítorí tìrẹ Ninefe:

"Ìwọ yóò ni irú-ọmọ láti máa jẹ́ orúkọ rẹ mọ́,

Èmi yóò pa ère fínfín àti ère dídà run

ó nínú tẹmpili àwọn ọlọ́run rẹ.

Èmi yóò wa ibojì rẹ,

nítorí ̀gbin ni ìwọ."

15 1.15: Isa 40.9; 52.7; Ap 10.36; Ro 10.15. ó, lórí àwọn òkè,

àwọn ẹsẹ̀ ẹni ó ìròyìn ayọ̀ ,

ẹni ó ń kéde àlàáfíà.

Ìwọ Juda, pa àṣẹ rẹ ó ìrònú mọ́,

ó san àwọn ̀jẹ́ rẹ.

Àwọn ènìyàn búburú yóò gbóguntì ́ mọ́;

wọn yóò parun pátápátá.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também

Naum
Ver todos os capítulos de Naum