Pular para o conteúdo
Publicidade

Jobu 22

Èsì Elifasi

1 Ìgbà náà ni Elifasi, ará Temani, dáhùn ,

2 22.2,3: Jb 35.6-8. "Ènìyàn è ṣe rere fún Ọlọ́run?

ọlọ́gbọ́n ti í ṣe rere fún ara rẹ̀?

3 Ohun ayọ̀ ha ni fún Olódùmarè olódodo ni ìwọ?

Tàbí èrè ni fún un ti ìwọ ̀rẹ̀ ?

4 "Yóò ha , nítorí ìbẹ̀

Ọlọ́run rẹ? Yóò ha lọ sínú ìdájọ́ ?

5 Ìwà búburú rẹ ha tóbi,

àti ̀ṣẹ̀ rẹ láìníye?

6 Nítòótọ́ ìwọ béèrè fún ààbò ni ọwọ́ arákùnrin rẹ láìnídìí,

ìwọ oníhòhò aṣọ wọn.

7 Ìwọ fi omi fún aláàárẹ̀ mu,

ìwọ háwọ́ oúnjẹ fún ẹni ebi ń pa.

8 ó ṣe ti alágbára , òun ni ó ilẹ̀,

ọlọ́tẹ̀sínú rẹ̀.

9 Ìwọ ti rán àwọn opó padà lọ ọwọ́ òfo,

apá àwọn ọmọ aláìní baba ti di ṣiṣẹ́.

10 Nítorí náà ni ìdẹ̀kùn ṣe káàkiri,

àti ìbẹ̀òjijì ń yọ ́ lẹ́nu.

11 Èéṣe òkùnkùn fi pọ̀ bẹ́̀ ìwọ fi ríran.

Èéṣe ̀pọ̀lọpọ̀ omi ́ mọ́lẹ̀.

12 "Ọlọ́run ha jẹ́ ẹni gíga ̀run?

wo orí àwọn ìràwọ̀ wọ́n ti ga !

13 Ìwọ , Ọlọ́run ti ṣe mọ̀?

Òun ha ṣe ìdájọ́ láti inú òkùnkùn ?

14 Ǹjẹ́ àwọsánmọ̀ ó nípọn jẹ ìbora fún un,

fi ríran; ó ń rìn nínú àyíká ̀run.

15 Ǹjẹ́ ìwọ fẹ́ rin ipa ̀ìgbàanì àwọn

ènìyàn búburú rìn?

16 A wọn lulẹ̀ kúrò nínú ayé láìpé ọjọ́ wọn,

ìpìlẹ̀ wọn ti da odò ṣíṣàn.

17 Àwọn ẹni ó fún Ọlọ́run , Lọ kúrò lọ́dọ̀ wa!

ni Olódùmarè yóò ṣe fún wọn?

18 Síbẹ̀ ó fi ohun rere kún ilé wọn!

Ṣùgbọ́n ìmọ̀ ènìyàn búburú jìnnà mi!

19 Àwọn olódodo ìparun wọn, wọ́n yọ̀,

àwọn aláìlẹ́ṣẹ̀ fi wọ́n rẹ́rìn-ín ẹlẹ́,

20 Lóòtítọ́ àwọn ̀wa ni a kúrò,

iná yóò oró wọn run.

21 "Fa ara rẹ súnmọ́ Ọlọ́run, ìwọ ó àlàáfíà;

nípa èyí ni rere yóò .

22 Èmi bẹ̀ ́, gba òfin láti ẹnu rẹ̀ ,

o to ̀rọ̀ rẹ̀ àyà rẹ.

23 ìwọ yípadà sọ́dọ̀ Olódùmarè, a gbé .

ìwọ ̀ṣẹ̀ jìnnà réré kúrò nínú àgọ́ rẹ,

24 ìwọ tẹ́ wúrà dáradára sílẹ̀,

lórí erùpẹ̀ àti wúrà Ofiri lábẹ́ òkúta odò,

25 nígbà náà Olódùmarè yóò jẹ́ wúrà rẹ,

àní yóò jẹ́ fàdákà fún ̀pọ̀lọpọ̀.

26 Lóòtítọ́ nígbà náà ìwọ ó inú dídùn nínú Olódùmarè,

ìwọ ó gbé ojú rẹ sókè sọ́dọ̀ Ọlọ́run.

27 ìwọ gbàdúrà rẹ sọ́dọ̀ rẹ̀, yóò gbọ́ tìrẹ,

ìwọ ó san ̀jẹ́ rẹ.

28 Ìwọ ó gbìmọ̀ ohun kan pẹ̀, yóò fi ìdí múlẹ̀ fún ;

ìmọ́lẹ̀ yóò mọ́ sípa ̀rẹ.

29 Nígbà ipa ̀rẹ lọ sísàlẹ̀,

nígbà náà ni ìwọ o , Ìgbésókè ń bẹ!

Ọlọ́run yóò gba onírẹ̀lẹ̀ !

30 Yóò gba ẹni í ṣe aláìjẹ̀bi ,

a ó gbà á nípa mímọ́ ọwọ́ rẹ̀."

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também