Pular para o conteúdo
Publicidade

Eksodu 13

Ìyàsímímọ́ àwọn àkọ́

1 Olúwa sọ fún Mose , 2 13.2,12,15: Lk 2.23."ya àwọn àkọ́yín ọkùnrin sọ́tọ̀ fún mi. Èyí ti ó jẹ́ àkọ́láàrín àwọn ọmọ Israẹli jẹ́ tèmi, ìbá à ṣe ènìyàn tàbí ẹranko."

3 Nígbà náà ni Mose sọ fún àwọn ènìyàn náà , "rántí ọjọ́ òní, ọjọ́ ti jáde kúrò ni ilẹ̀ Ejibiti, kúrò ilẹ̀ ̀yin ti ń ṣe ẹrú, nítorí Olúwa un yín jáde kúrò ni inú rẹ̀ pẹ̀ọwọ́ agbára. ṣe jẹ ohunkóhun ó ni ìwúkàrà nínú. 4 Òní, oṣù Abibu (oṣù kẹta ọdún tiwa) lónìí ̀yin ń jáde kúrò Ejibiti. 5 ìgbà Olúwa un yín jáde ilẹ̀ Kenaani, Hiti, Amori, Hifi àti ilẹ̀ àwọn Jebusi; ilẹ̀ ó ti ṣe búra láti fi fún àwọn baba ńlá yín, ilẹ̀ ó ń sàn fún wàrà àti oyin, ni láti pa ìsìn yìí mọ́ oṣù yìí. 6 Fún ọjọ́ méje ni ìwọ yóò fi jẹ àkàrà ìwúkàrà nínú àti ọjọ́ keje ni àjọ yóò fún Olúwa. 7 ̀yin ó jẹ àkàrà ìwúkàrà fún ọjọ́ méje yìí; ṣe ohunkóhun a fi ìwúkàrà ṣe sàkání yín. 8 ọjọ́ náà, ìwọ yóò sọ fún àwọn ọmọ rẹ ọkùnrin, Mo ń ṣe èyí nítorí ohun Olúwa ṣe fún mi nígbà èmi jáde kúrò ni ilẹ̀ Ejibiti.9 Ṣíṣe èyí yóò fún àmì ọwọ́ rẹ, àti àmì ìrántí ni iwájú orí rẹ, yóò máa rán létí òfin Olúwa ẹnu rẹ. Nítorí Olúwa jáde láti ilẹ̀ Ejibiti pẹ̀ọwọ́ agbára ńlá rẹ̀. 10 Ìwọ gbọdọ̀ pa òfin náà mọ́ àkókò a yàn ọdún ń gorí ọdún.

11 "Lẹ́yìn Olúwa ilẹ̀ àwọn ará Kenaani ó fi fún gẹ́gẹ́ òun ti ṣe ìlérí pẹ̀ìbúra fún àti fún àwọn baba ńlá rẹ̀, 12 13.12: Ek 34.19,20; Lk 2.23.ìwọ yóò fi àkọ́inú rẹ fún Olúwa. Gbogbo àkọ́ti ó jẹ́ akọ ti ẹran ̀sìn rẹ ó jẹ́ ti Olúwa. 13 Ìwọ yóò fi ̀dọ́-àgùntàn ra àkọ́kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ padà, ṣùgbọ́n ìwọ á padà, ǹjẹ́ ìwọ ṣẹ́ ọrùn, gbogbo àkọ́ọkùnrin ni ìwọ ó padà.

14 "Yóò ṣe àwọn ọjọ́ ń bọ̀, ìgbà àwọn ọmọ yín yóò béèrè lọ́wọ́ yín, ni èyí túmọ̀ ?ìwọ ó sọ fún wọn , Pẹ̀ọwọ́ agbára Olúwa fi wa jáde kúrò ni ilẹ̀ Ejibiti, kúrò oko ẹrú. 15 ìgbà ti Farao ṣe orí kunkun, ti ó kọ̀ láti jẹ́ a lọ, Olúwa pa gbogbo àwọn àkọ́ilẹ̀ Ejibiti, àti ènìyàn àti ẹranko. Ìdí èyí ni àwa fi ń fi gbogbo àkọ́í ṣe akọ ẹbọ Olúwa láti fi ṣe ìràpadà fún àwọn àkọ́wa ọkùnrin.16 Èyí yóò jẹ́ àmì ni ọwọ́ yín àti àmì iwájú orí yín Olúwa wa jáde láti ilẹ̀ Ejibiti pẹ̀ọwọ́ agbára ńlá."

Kíkọjá ni Òkun Pupa

17 ìgbà Farao jẹ́ àwọn ènìyàn ó lọ, Ọlọ́run wọn tọ ojú ̀ti ó la orílẹ̀-èdè àwọn Filistini kọjá, o tilẹ̀ jẹ́ ̀náà kúrú. Nítorí Ọlọ́run sọ , "wọ́n dojúkọ ogun, wọ́n ọkàn wọn padà wọ́n padà ilẹ̀ Ejibiti." 18 Nítorí náà Ọlọ́run darí àwọn ènìyàn rọkọ gba ̀aginjù apá Òkun Pupa. Àwọn ọmọ Israẹli jáde kúrò ilẹ̀ Ejibiti pẹ̀ìmúra fún ogun.

19 13.19: Gẹ 50.25. Mose egungun Josẹfu pẹ̀rẹ̀ nítorí Josẹfu àwọn ọmọ Israẹli búra. Ó ti , "Dájúdájú Ọlọ́run yóò dìde fún ìrànlọ́wọ́ yín gbọdọ̀ egungun mi lọ pẹ̀yín kúrò níhìn-ín yìí."

20 Wọ́n ̀wọn pọ̀n láti Sukkoti lọ, wọ́n pàgọ́ Etamu etí aginjù. 21 Olúwa ń lọ níwájú wọn, nínú ̀wọ̀n ìkùùkuu ̀sán láti máa ṣe amọ̀wọn àti òru nínú ̀wọ̀n iná láti máa tan ìmọ́lẹ̀ fún wọn, wọn máa lọ nínú ìrìnàjò wọn tọ̀sán tòru. 22 Ìkùùkuu náà kúrò ààyè rẹ̀ ̀sán, bẹ́̀ ni, ̀wọ̀n iná kúrò ààyè rẹ̀ ni òru, iwájú àwọn ènìyàn náà.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também