Pular para o conteúdo
Publicidade

Eksodu 29

Ìyàsímímọ́ Àwọn Àlùfáà

1 29.1-37: Le 8.1-34. "Èyí ni ohun ìwọ yóò ṣe láti wọ́n mímọ́, wọn máa ṣe àlùfáà fún mi. ̀dọ́ akọ màlúù kan àti àgbò méjì àbùkù. 2 Láti ara ìyẹ̀fun aláìwú dídùn, ṣe àkàrà àti àkàrà a pẹ̀òróró, àti àkàrà fẹ́lẹ́fẹ́lẹ́ aláìwú a da òróró . 3 Ìwọ yóò wọn sínú apẹ̀rẹ̀ kan, ìwọ yóò wọn nínú apẹ̀rẹ̀ náà papọ̀ pẹ̀akọ màlúù àti àgbò méjì náà. 4 Nígbà náà ni ìwọ yóò Aaroni àti àwọn ọmọ rẹ̀ ẹnu-ọ̀àgọ́ àjọ, ìwọ yóò fi omi wẹ̀ wọ́n. 5 Ìwọ yóò fi ̀àwọ̀tẹ́lẹ̀ wọ Aaroni, àti aṣọ ìgúnwà efodu, àti efodu, àti ìgbàyà, ó fi onírúurú ọnà ̀̀efodu í. 6 Ìwọ yóò fi fìlà e orí, ìwọ yóò ṣe adé mímọ́ sára fìlà náà. 7 Nígbà náà ni ìwọ yóò òróró ìtasórí, ìwọ yóò á mímọ́ nípa dída òróró i orí. 8 Ìwọ yóò àwọn ọmọ rẹ̀ ìwọ yóò fi aṣọ àwọ̀tẹ́lẹ̀ wọ̀ wọ́n 9 ìwọ yóò fi fìlà wọn ni orí. Nígbà náà fi ̀àmùrè di Aaroni àti àwọn ọmọ rẹ̀. Iṣẹ́ àlùfáà yóò máa jẹ́ tiwọn ìlànà títí ayé.

"Báyìí ni ìwọ yóò ya Aaroni àti àwọn ọmọ rẹ̀ mímọ́.

10 "Ìwọ yóò akọ màlúù síwájú àgọ́ àjọ, Aaroni àti àwọn ọmọ rẹ̀ yóò fi ọwọ́ wọn akọ màlúù orí. 11 Ìwọ yóò pa àwọn akọ màlúù náà níwájú Olúwa ẹnu-ọ̀àgọ́ àjọ. 12 Ìwọ yóò nínú ̀jẹ̀ akọ màlúù náà, ìwọ yóò fi ìka rẹ tọ́ sára ìwo pẹpẹ náà, o da gbogbo ̀jẹ̀ tókù ìsàlẹ̀ pẹpẹ náà. 13 o gbogbo ̀ó inú , èyí ó bo ̀dọ̀ àti ìwé méjèèjì pẹ̀̀ó lára wọn, ìwọ yóò sun wọ́n lórí pẹpẹ. 14 Ṣùgbọ́n fi iná sun ẹran akọ màlúù, awọ rẹ̀ àti ìgbẹ́ rẹ̀ lẹ́yìn òde. Ẹbọ ̀ṣẹ̀ ni.

15 "Ìwọ yóò àgbò kan, Aaroni àti àwọn ọmọ rẹ̀ yóò gbọ́wọ́ orí àgbò náà. 16 Ìwọ yóò pa àgbò náà, ìwọ yóò ̀jẹ̀ rẹ̀, ìwọ yóò fi wọ́n pẹpẹ náà yíká. 17 Ìwọ yóò àgbò náà wẹ́wẹ́, ìwọ yóò fọ inú àti àwọn ẹsẹ̀ rẹ̀, ìwọ yóò wọ́n pẹ̀orí rẹ̀ ara wọn. 18 29.18: Ef 5.2; Fp 4.18.Nígbà náà ni ìwọ yóò sun àgbò náà lórí pẹpẹ. Ẹbọ sísun ni Olúwa, olóòórùn dídùn ni, ẹbọ ti a fi iná ṣe Olúwa ni.

19 "Ìwọ yóò àgbò kejì, Aaroni àti àwọn ọmọ rẹ̀ yóò fi ọwọ́ wọn àgbò náà lórí. 20 Ìwọ yóò pa àgbò náà, ìwọ yóò nínú ̀jẹ̀ rẹ̀, ìwọ yóò tọ́ etí ̀tún Aaroni àti àwọn ọmọ rẹ̀, àtàǹpàkò ọwọ́ ̀tún wọn, àti àtàǹpàkò ẹsẹ̀ ̀tún wọn. Ìwọ yóò fi ̀jẹ̀ wọ́n pẹpẹ náà yíká. 21 Ìwọ yóò nínú ̀jẹ̀ ó lórí pẹpẹ àti nínú òróró ìtasórí, ìwọ yóò wọ́n ọn sára Aaroni àti sára aṣọ rẹ̀, sára àwọn ọmọ rẹ àti sára aṣọ wọn. Nígbà náà ni òun àti àwọn ọmọ rẹ̀ àti aṣọ wọn yóò di mímọ́.

22 "Ìwọ yóò lára ̀àgbò náà, ìrù ó lọ́ràá, ̀ó inú , èyí ti ó bo ̀dọ̀, ìwé méjèèjì pẹ̀̀ó lára wọn àti itan ̀tún. (Èyí ni àgbò fún ìyàsímímọ́.) 23 Láti inú apẹ̀rẹ̀ ìṣù àkàrà aláìwú, èyí ó níwájú Olúwa, ìṣù kan, àkàrà a fi òróró dín àti àkàrà fẹ́lẹ́fẹ́lẹ́ kan. 24 Ìwọ yóò fi gbogbo rẹ̀ Aaroni àti àwọn ọmọ rẹ̀ lọ́wọ́, ìwọ yóò wọ́n gẹ́gẹ́ ẹbọ fífì níwájú Olúwa. 25 Nígbà náà ni ìwọ yóò gbà wọ́n ọwọ́ wọn, ìwọ yóò sun wọ́n lórí pẹpẹ pẹ̀ẹbọ sísun fún òórùn dídùn níwájú Olúwa, ẹbọ ti a fi iná sun Olúwa. 26 Ìwọ yóò igẹ̀ àgbò ìyàsímímọ́ Aaroni, ìwọ yóò si ì ni ẹbọ fífì níwájú Olúwa; ìpín tìrẹ ni èyí.

27 "Ìwọ yóò ya igẹ̀ ẹbọ fífì náà mímọ́, àti ìtàn ẹbọ à gbé sọ sókè a , a gbé sọ sókè nínú àgbò ìyàsímímọ́ náà, àní nínú èyí í ṣe Aaroni àti nínú èyí ì ṣe àwọn ọmọ rẹ̀. 28 Èyí ni yóò máa ṣe ìpín ti Aaroni àti àwọn ọmọ rẹ̀ láti ọwọ́ àwọn ọmọ Israẹli nígbà gbogbo. Nítorí ẹbọ à gbé sọ sókè ni ẹbọ yóò ṣì ṣe èyí ni ẹbọ àwọn ọmọ Israẹli yóò máa ṣe Olúwa láti inú ẹbọ àlàáfíà wọn.

29 "Aṣọ mímọ́ Aaroni yóò jẹ́ ti irú àwọn ọmọ rẹ̀, nítorí a máa fi òróró yàn wọ́n a máa wọ́n mímọ́. 30 Ọmọ rẹ̀ ó jẹ àlùfáà ipò rẹ̀, ó wọ̀ yóò máa àgọ́ àjọ láti ṣiṣẹ́ Ibi Mímọ́, yóò máa wọ̀ wọ́n ọjọ́ méje.

31 "Ìwọ yóò àgbò fún ìyàsímímọ́, ìwọ yóò bọ ẹran rẹ̀ ibi mímọ́ kan. 32 ẹnu-ọ̀àgọ́ àjọ ni Aaroni àti àwọn ọmọ rẹ̀ yóò ti jẹ ẹran àgbò náà àti àkàrà náà ó nínú apẹ̀rẹ̀. 33 Wọn yóò jẹ nǹkan wọ̀nyí èyí a fi ṣe ètùtù náà fún ìyàsímímọ́ àti ìsọdimímọ́ wọn. Ṣùgbọ́n àlejò ni gbọdọ̀ jẹ nínú rẹ̀, nítorí mímọ́ ni. 34 ohun kan nínú ẹran àgbò ìyàsímímọ́ tàbí nínú àkàrà náà di òwúrọ̀, nígbà náà ni ìwọ fi iná sun wọn. A gbọdọ̀ jẹ ́, nítorí mímọ́ ni.

35 "Báyìí ni ìwọ yóò ṣì ṣe fún Aaroni àti àwọn ọmọ rẹ̀ ohun gbogbo ti mo paláṣẹ fún , ọjọ́ méje ni ìwọ yóò fi wọ́n mímọ́. 36 Ìwọ yóò máa pa akọ màlúù kọ̀̀kan ojoojúmọ́ ẹbọ ̀ṣẹ̀ láti ṣe ètùtù. Ìwọ yóò wẹ pẹpẹ mọ́ nípa ṣíṣe ètùtù fún un, ìwọ yóò ta òróró i láti sọ ́ mímọ́. 37 ọjọ́ méje ni ìwọ yóò ṣe ètùtù pẹpẹ náà, ìwọ yóò sọ ́ di mímọ́. Nígbà náà ni pẹpẹ náà yóò jẹ́ mímọ́ jùlọ, àti ohunkóhun ó fi ọwọ́ kàn án yóò jẹ́ mímọ́.

38 29.38-42: Nu 28.3-10. "Èyí ni ìwọ yóò máa fi ẹbọ orí pẹpẹ náà: ̀dọ́-àgùntàn méjì ọlọ́dún kan ni ojoojúmọ́ láéláé. 39 ̀dọ́-àgùntàn kan ni ìwọ yóò fi ẹbọ òwúrọ̀ àti ̀dọ́-àgùntàn èkejì àṣálẹ́. 40 Pẹ̀̀dọ́-àgùntàn ti àkọ́kọ́ ẹbọ ìdámẹ́wàá òsùwọ̀n ìyẹ̀fun dídára a fi ìdámẹ́rin hínì òróró lára olifi a gún, àti ìdámẹ́rin hínì wáìnì ẹbọ mímu. 41 ̀dọ́-àgùntàn kejì ni ìwọ ó pa ẹbọ àṣálẹ́ ìwọ yóò ṣe í gẹ́gẹ́ ẹbọ jíjẹ àti ẹbọ mímu ti òwúrọ̀ fún òórùn dídùn, ẹbọ a fi iná ṣe ni Olúwa.

42 "Fún ìrandíran ń bọ̀, ni ó máa ṣe ẹbọ sísun nígbà gbogbo ẹnu-ọ̀àgọ́ àjọ níwájú Olúwa. Níbẹ̀ èmi yóò pàdé yín, èmi yóò a yín sọ̀rọ̀; 43 níbẹ̀ tún ni èmi yóò pàdé àwọn ọmọ Israẹli, a ó fi ògo mi ya àgọ́ náà mímọ́.

44 "Bẹ́̀ ni èmi yóò ya àgọ́ àjọ náà mímọ́ àti pẹpẹ náà, èmi yóò ya Aaroni àti àwọn ọmọ rẹ̀ mímọ́ láti máa ṣe iṣẹ́ àlùfáà fún mi. 45 Nígbà náà ni èmi yóò máa gbé láàrín àwọn ọmọ Israẹli, èmi yóò máa ṣe Ọlọ́run wọn. 46 Wọn yóò mọ̀ Èmi ni Olúwa Ọlọ́run wọn, ẹni ó wọn jáde láti ilẹ̀ Ejibiti , nítorí èmi máa gbé àárín wọn. Èmi ni Olúwa Ọlọ́run wọn.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também