Pular para o conteúdo
Publicidade

Eksodu 39

Aṣọ àlùfáà

1 Nínú aṣọ aláró, ti elése àlùkò àti ti òdòdó ni wọ́n fi ṣe aṣọ híhun fún àwọn òṣìṣẹ́ ibi mímọ́. Ó tún aṣọ mímọ́ fún Aaroni gẹ́gẹ́ Olúwa ti pàṣẹ fún Mose.

̀efodu

2 39.2-7: Ek 28.6-12. Ó ṣe ̀efodu wúrà, ti aṣọ aláró, ti elése àlùkò, ti òdòdó àti ti ̀gbọ̀ olókùn dáradára. 3 Ó lu wúrà náà di ewé fẹ́lẹ́fẹ́lẹ́, ó tún e láti fi ṣe iṣẹ́ aṣọ aláró, ti elése àlùkò, ti òdòdó, àti sínú ̀gbọ̀ dáradára, iṣẹ́ ọlọ́. 4 Ó ṣe aṣọ èjìká fún ̀efodu náà, èyí ó so mọ igun rẹ̀ méjèèjì, nítorí ó so ó pọ̀. 5 Ọnà ìgbànú híhun rẹ̀ i ti rẹ̀ ó bákan náà pẹ̀̀efodu ó e pẹ̀wúrà, àti pẹ̀aṣọ aláró, elése àlùkò, òdòdó àti pẹ̀̀gbọ̀ olókùn dáradára, gẹ́gẹ́ Olúwa ti pàṣẹ fún Mose.

6 Ó ṣiṣẹ́ òkúta óníkìsì a ojú ìdè wúrà, a fín wọn gẹ́gẹ́ èdìdì pẹ̀orúkọ àwọn ọmọ Israẹli. 7 Ó so wọ́n mọ́ aṣọ èjìká ̀efodu náà òkúta ìrántí fún àwọn ọmọ Israẹli, gẹ́gẹ́ Olúwa ti pàṣẹ fún Mose.

Ìgbàyà

8 39.8-21: Ek 28.15-28. Ó ṣe iṣẹ́ ọnà ìgbàyà náà iṣẹ́ ọgbọ́n ọlọ́. Ó ṣe é ̀efodu: ti wúrà ti aṣọ aláró, ti elése àlùkò, ti òdòdó àti ti ̀gbọ̀ olókùn dáradára. 9 Igun rẹ̀ mẹ́rẹ̀̀rin rẹ̀ ṣe déédé ìwọ̀n ìka kan ìnà rẹ̀, ìwọ̀n ìka kan ìbú rẹ̀, ó jẹ́ ìṣẹ́po méjì. 10 Ó to ipele òkúta oníyebíye mẹ́rin i. ipele kìn-ín-ní rúbì , topasi àti berili; 11 ipele kejì, turikuose, safire, emeradi àti diamọndi; 12 ipele kẹta, jasiniti, agate àti ametisiti; 13 ipele kẹrin, karisoliti, óníkìsì, àti jasperi. Ó wọ́n ojú ìdè wúrà títò wọn. 14 Wọ́n jẹ́ òkúta méjìlá, ̀kan fún orúkọ àwọn ọmọ Israẹli kọ̀̀kan, a fín ̀kọ̀̀kan gẹ́gẹ́ èdìdì pẹ̀orúkọ ẹnìkọ̀̀kan ̀méjèèjìlá.

15 Fún ìgbàyà náà, wọ́n ṣe ̀wọ̀n iṣẹ́ kìkì wúrà, gẹ́gẹ́ bi okùn. 16 Wọ́n ṣe ojú ìdè wúrà méjì àti òrùka wúrà méjì, wọ́n so àwọn òkúta náà mọ́ igun méjèèjì ìgbàyà náà. 17 Wọ́n so ̀wọ̀n wúrà méjèèjì náà mọ́ àwọn òrùka náà ni igun ìgbàyà náà, 18 àti àwọn òpin ̀wọ̀n tókù ni wọ́n fi mọ ojú ìdè méjèèjì, wọ́n so wọ́n mọ́ aṣọ èjìká ̀efodu náà iwájú. 19 Wọ́n ṣe òrùka wúrà méjì, wọ́n so wọ́n mọ́ igun méjèèjì ìgbàyà náà etí ó inú lẹ́gbẹ̀́ ̀efodu náà. 20 Wọ́n túnṣe òrùka wúrà méjì i, wọ́n so wọ́n mọ́ ìdí aṣọ èjìká iwájú ̀efodu náà ó súnmọ́ ibi a ṣe lọ́ṣọ̀́ òkè ìgbànú ̀efodu náà. 21 Wọn so àwọn òrùka ìgbàyà mọ́ àwọn òrùka ̀efodu ̀aṣọ aláró, a pa á pọ̀ mọ́ ìgbànú, nítorí ìgbàyà náà ṣe kúrò lára ̀efodu náà gẹ́gẹ́ Olúwa ti pàṣẹ fún Mose.

Àwọn aṣọ àlùfáà mìíràn

22 39.22-26: Ek 28.31-34. Ó ṣe ̀àmùrè ̀efodu gbogbo rẹ̀ jẹ́ aṣọ aláró iṣẹ́ aláṣọ híhun, 23 pẹ̀ihò àárín ̀àmùrè náà gẹ́gẹ́ i ojú kọ́, àti ìgbànú ihò yìí , nítorí ó ba à ya. 24 Ó ṣe pomegiranate ti aṣọ aláró, elése àlùkò, òdòdó àti ti ̀gbọ̀ olókùn dáradára ìṣẹ́̀àmùrè náà . 25 Ó ṣe agogo kìkì wúrà, ó so wọ́n mọ́ àyíká ìṣẹ́àárín pomegiranate náà. 26 Ago àti pomegiranate kọjú àyíká ìṣẹ́̀àmùrè láti máa wọ̀ ́ fún iṣẹ́ àlùfáà, Olúwa ti pàṣẹ fún Mose.

27 39.27-29: Ek 28.39,40,42. Fún Aaroni àti àwọn ọmọ rẹ, wọ́n ṣe àwọ̀tẹ́lẹ̀ ti ̀gbọ̀ dáradára iṣẹ́ aláṣọ híhun. 28 Àti fìlà ̀gbọ̀ dáradára, ìgbàrí ̀gbọ̀ àti aṣọ abẹ́ ̀gbọ̀ olókùn dáradára. 29 ̀náà jẹ́ ti ̀gbọ̀ olókùn dáradára, aṣọ aláró, elése àlùkò àti òdòdó a fi iṣẹ́ abẹ́rẹ́ ṣe Olúwa ṣe pàṣẹ fún Mose.

30 39.30-31: Ek 28.36,37. Ó ṣe àwo, adé mímọ́, láti ara kìkì wúrà, wọ́n kọ̀i, gẹ́gẹ́ i ìkọ̀lórí èdìdì:

Mímọ́ Olúwa.

31 Wọ́n so ̀aláró mọ́ ọn láti ṣo ó mọ́ fìlà náà, gẹ́gẹ́ Olúwa ti pàṣẹ fún Mose.

Mose bẹ àgọ́ náà

32 Bẹ́̀ ni gbogbo iṣẹ́ àgọ́ náà, ti àgọ́ àjọ parí. Àwọn ọmọ Israẹli ṣe ohun gbogbo gẹ́gẹ́ Olúwa ti pàṣẹ fún Mose. 33 Wọ́n tabanaku náà tọ Mose :

àgọ́ náà àti gbogbo ohun ̀ṣọ́ rẹ̀, ìkọ́ rẹ̀, pákó rẹ̀, ̀rẹ̀, òpó rẹ̀ àti àwọn ihò ìtẹ̀bọ̀ rẹ̀;

34 ìbòrí awọ àgbò a kùn pupa, ìbòrí awọ àti ìji aṣọ títa;

35 àpótí ̀pẹ̀àwọn òpó rẹ̀ àti ìbòrí àánú;

36 39.36: Ek 25.30; 40.23; Le 24.5-9. tábìlì pẹ̀gbogbo ohun èlò rẹ̀ àti àkàrà ìfihàn;

37 ̀fìtílà kìkì wúrà pẹ̀ipele fìtílà rẹ̀ àti gbogbo ohun èlò rẹ̀, àti òróró fún títanná rẹ̀;

38 pẹpẹ wúrà àti òróró ìtasórí, tùràrí dídùn, àti aṣọ títa fún ẹnu-ọ̀àgọ́ náà.

39 Pẹpẹ idẹ pẹ̀idẹ ọlọ, àwọn òpó rẹ̀ àti gbogbo ohun èlò rẹ̀;

agbada pẹ̀ẹsẹ̀ rẹ̀;

40 aṣọ títa ti àgbàlá pẹ̀àwọn òpó rẹ̀ àti àgbàlá, àti aṣọ títa fún ẹnu-ọ̀àgbàlá;

̀àmùrè àti èèkàn àgọ́ fún àgbàlá náà;

gbogbo ohun ̀ṣọ́ fún àgọ́, àgọ́ àjọ náà;

41 aṣọ híhun wọ́n ń wọ̀ fún iṣẹ́ ibi mímọ́, aṣọ mímọ́ fún Aaroni àlùfáà àti aṣọ fún àwọn ọmọ rẹ̀ nígbà wọ́n ń ṣiṣẹ́ àlùfáà.

42 Àwọn ọmọ Israẹli ti ṣe gbogbo iṣẹ́ náà gẹ́gẹ́ Olúwa ti pàṣẹ fún Mose. 43 Mose bẹ iṣẹ́ náà , ó i wọ́n ti ṣe é gẹ́gẹ́ Olúwa ti pàṣẹ. Nítorí náà Mose bùkún fún wọn.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também