Pular para o conteúdo
Publicidade

Eksodu 9

Ààrùn lára ẹran ̀sìn

1 Nígbà náà ni Olúwa sọ fún Mose , "Lọ sọ fún Farao, Èyí ni Olúwa Ọlọ́run àwọn Heberu sọ, "Jẹ́ àwọn ènìyàn Mi ó lọ, wọn à sìn ." 2 ìwọ kọ̀ láti jẹ́ wọn ó lọ, ó wọn dúró. 3 Ọwọ́ Olúwa yóò ààrùn búburú ara ẹran ̀sìn nínú oko, ara ẹṣin, kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́, ìbákasẹ, màlúù, àgùntàn àti ewúrẹ́ yín. 4 Ṣùgbọ́n Olúwa yóò pààlà àárín ẹran ̀sìn ó jẹ́ ti Israẹli àti ti àwọn ara Ejibiti yóò fi jẹ́ ẹran ̀sìn ti ó jẹ́ ti ará Israẹli yóò kùú.’ "

5 Olúwa àkókò kan , "̀la ni Olúwa yóò ṣe èyí ni ilẹ̀ yìí." 6 Olúwa ṣe é ni ọjọ́ kejì. Gbogbo ẹran ̀sìn ará Ejibiti , ṣùgbọ́n ẹyọ kan lára ẹran ̀sìn àwọn Israẹli. 7 Farao rán àwọn ènìyàn rẹ̀ láti lọ ṣe ìwádìí, wọ́n ẹyọ kan lára àwọn ẹran ̀sìn ará Israẹli. Síbẹ̀ náà, Farao ọkàn rẹ̀ padà àti jẹ́ àwọn ènìyàn ó lọ.

Ààrùn Oówo

8 Nígbà náà ni Olúwa sọ fún Mose àti Aaroni, "bu ̀kúnwọ́ eérú gbígbóná láti inú ààrò, Mose ú inú afẹ́fẹ́ ni iwájú Farao. 9 Yóò di eruku lẹ́búlẹ́ni gbogbo ilẹ̀ Ejibiti, yóò di oówo ti ń pẹ̀ìléròrò ara àwọn ènìyàn àti ẹran jákèjádò gbogbo ilẹ̀ Ejibiti."

10 9.10: If 16.2. Nígbà náà ni wọ́n eérú gbígbóná láti inú ààrò, wọ́n dúró iwájú Farao. Mose ku eérú náà sínú afẹ́fẹ́, ó di oówo ń pẹ̀ìléròrò ni ara àwọn ènìyàn àti lára ẹran. 11 Àwọn onídán le è dúró níwájú Mose nítorí oówo ti ó lára wọn àti ni ara gbogbo àwọn ara Ejibiti. 12 Ṣùgbọ́n Ọlọ́run ọkàn Farao le, gbọ́ ti Mose àti Aaroni, gẹ́gẹ́ Olúwa ti sọ fún Mose.

Òjò o yìnyín

13 Nígbà náà ni Olúwa sọ fún Mose , "Dìde ni òwúrọ̀ kùtùkùtù, o tọ Farao lọ, o fún un , Èyí ni ohun Olúwa Ọlọ́run àwọn Heberu , Jẹ́ àwọn ènìyàn mi ó lọ, wọn à sìn , 14 nítorí nígbà yìí ni èmi yóò rán àjàkálẹ̀-ààrùn ti ó agbára gidigidi , àwọn ìjòyè rẹ àti àwọn ènìyàn rẹ, ìwọ ó mọ̀ , ẹni èmi ni gbogbo ayé. 15 Ó ti yẹ n ti na ọwọ́ mi jáde láti kọlù ́ àti àwọn ènìyàn rẹ pẹ̀ààrùn búburú ti ti run yín kúrò ni orí ilẹ̀. 16 9.16: Ro 9.17.Ṣùgbọ́n nítorí èyí ni èmi ṣe dúró, èmi ó le fi agbára mi hàn lára rẹ, àti a à le máa ròyìn orúkọ mi gbogbo ayé. 17 Síbẹ̀ ìwọ tún gbógun ti àwọn ènìyàn mi, ìwọ jẹ́ wọn lọ. 18 Nítorí náà, ni ìwòyí ̀la, Èmi yóò rán òjò o yìnyín irú rẹ̀ i rọ̀ ni Ejibiti láti ìpilẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀ títí di àkókò yìí. 19 Pàṣẹ nísinsin yìí láti ẹran ̀sìn yín àti ohun gbogbo ti ni pápá abẹ́ ààbò, nítorí òjò yìnyín yóò rọ̀ orí àwọn ènìyàn àti ẹran ti a abẹ́ ààbò wọ́n ni orí pápá, wọn yóò .’ "

20 Àwọn ti ó bẹ̀̀rọ̀ Olúwa lára àwọn ìjòyè Farao yára lọ láti àwọn ẹrú àti àwọn ẹran ̀sìn wọn abẹ́ ààbò. 21 Ṣùgbọ́n àwọn ti ̀rọ̀ Olúwa fi àwọn ẹrú wọn àti àwọn ẹran ̀sìn wọn sílẹ̀ ni pápá.

22 Olúwa sọ fún Mose , "Gbé ọwọ́ rẹ sókè ̀run yìnyín à rọ̀ orí gbogbo ilẹ̀ Ejibiti, orí ènìyàn àti ẹranko, àti orí gbogbo ohun ̀gbìn ó ni inú oko." 23 9.23,24: If 8.7; 16.21.Nígbà Mose gbé ̀rẹ̀ sókè ojú ̀run, Olúwa rán àrá àti yìnyín, mọ̀nàmọ́bùsi orí ilẹ̀. Olúwa rọ òjò yìnyín orí ilẹ̀ Ejibiti. 24 Yìnyín rọ̀, mọ̀nàmọ́bẹ̀rẹ̀ bùsi orí ilẹ̀ èyí ni ó ì burú ti ó ṣẹlẹ̀ láti ìgbà ti Ejibiti ti di orílẹ̀-èdè. 25 Jákèjádò gbogbo ilẹ̀ Ejibiti ni yìnyín ti pa gbogbo ohun ó ni orí pápá; ènìyàn àti ẹranko, ó gbogbo ohun ̀gbìn lulẹ̀ ó fa gbogbo igi ya pẹ̀. 26 Ilẹ̀ Goṣeni ni ibi ti àwọn Israẹli nìkan ni òjò yìnyín náà rọ̀ .

27 Nígbà náà ni Farao pe Mose àti Aaroni ̀dọ́ rẹ̀, ó fún wọn , "Èmi ti ṣẹ̀ àkókò yìí; Olúwa jẹ́ olódodo ṣùgbọ́n èmi àti àwọn ènìyàn mi ni aláìṣòdodo. 28 Èyí ti òjò yìnyín àti àrá rọ̀ yìí gẹ́́, gbàdúrà Olúwa ó dáwọ́ rẹ̀ dúró. Èmi yóò jẹ́ lọ, n tún ni a yín dúró mọ́."

29 Mose a lóhùn , "mo ti jáde kúrò àárín ìlú, èmi yóò gbé ọwọ́ mi sókè Olúwa, sísán àrá yóò dáwọ́ dúró, yìnyín ni rọ̀ mọ́, ìwọ ó mọ̀ Olúwa ni ó ni ilẹ̀. 30 Ṣùgbọ́n èmi mọ̀ síbẹ̀síbẹ̀ ìwọ àti àwọn ìjòyè rẹ bẹ̀Olúwa Ọlọ́run."

31 (A lu ̀gbọ̀ àti ọkà barle bolẹ̀; nítorí barle ìpẹ́, ̀gbọ̀ rudi. 32 Alikama àti ọkà ni a bolẹ̀, nítorí wọ́n ì dàgbà.)

33 Nígbà náà ni Mose jáde kúrò ni iwájú Farao, ó kúrò ni àárín ìgboro kọjá lọ ̀yìn odi ìlú, ó gbé ọwọ́ rẹ̀ sókè Olúwa, sísán àrá àti òjò yìnyín ti ń rọ̀ dáwọ́ dúró, òjò rọ̀ orí ilẹ̀ mọ́. 34 Nígbà Farao i òjò àti yìnyín àti àrá ti ń sán ti dáwọ́ dúró, ó tún ṣẹ̀ ̀̀kan i. Òun àti àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀ ṣì àyà wọn le. 35 Àyà Farao le, bẹ́̀ ni jẹ́ àwọn ọmọ Israẹli ó lọ, Olúwa ti sọ láti ẹnu Mose.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também