Pular para o conteúdo
Publicidade

Eksodu 28

Aṣọ àlùfáà

1 "Ìwọ Aaroni arákùnrin rẹ ̀dọ̀ rẹ, un kúrò ni àárín àwọn ọmọ Israẹli, pẹ̀àwọn ọmọ rẹ̀ Nadabu, Abihu, Eleasari, àti Itamari, wọn ó sìn gẹ́gẹ́ àlùfáà. 2 Ìwọ yóò aṣọ mímọ́ fún Aaroni arákùnrin rẹ, láti fún un ni ̀ṣọ́ àti ọlá. 3 Ìwọ yóò sọ fún gbogbo àwọn ọlọ́gbọ́n ènìyàn, àwọn ẹni mo fún ọgbọ́n, wọn ó aṣọ fún Aaroni, fún ìyàsímímọ́ rẹ̀, ó ba à sìn gẹ́gẹ́ àlùfáà. 4 Wọ̀nyí ni àwọn aṣọ wọn yóò : ìgbàyà kan, ̀efodu, ̀àmùrè kan, ̀àwọ̀tẹ́lẹ̀ ọlọ́, fìlà àti aṣọ ìgúnwà. wọn ó àwọn aṣọ mímọ́ yìí fún Aaroni arákùnrin rẹ àti àwọn ọmọ rẹ̀, wọn ó sìn gẹ́gẹ́ àlùfáà. 5 Wọn yóò lo wúrà, aṣọ aláró, elése àlùkò àti ti òdòdó àti ti ̀gbọ̀ dáradára.

̀efodu

6 28.6-12: Ek 39.2-7. "Wọn yóò ̀efodu ti wúrà, aṣọ aláró, elése àlùkò àti ti òdòdó àti ti ̀gbọ̀ olókùn wíwẹ́, iṣẹ́ ọlọ́. 7 ó ni aṣọ èjìká méjì a so mọ́ igun rẹ̀ méjèèjì, a so ó pọ̀. 8 Àti onírúurú ọnà ̀rẹ̀, ó ni orí rẹ̀, yóò bákan náà, gẹ́gẹ́ bi iṣẹ́ rẹ̀, wúrà, ti aṣọ aláró, òdòdó àti ̀gbọ̀ olókùn wíwẹ́.

9 "Ìwọ yóò òkúta óníkìsì méjì, ìwọ yóò fín orúkọ àwọn ọmọ Israẹli sára wọn. 10 ti ìbí wọn, orúkọ àwọn mẹ́sára òkúta kan àti orúkọ àwọn mẹ́tókù sára òkúta kejì. 11 Iṣẹ́ ọnà òkúta fínfín, ìfín èdìdì àmì, ni ìwọ yóò fún òkúta méjèèjì gẹ́gẹ́ orúkọ àwọn ọmọ Israẹli: ìwọ yóò wọ́n ojú ìdè wúrà. 12 Ìwọ yóò so wọ́n pọ̀ mọ́ èjìká efodu náà òkúta ìrántí fún àwọn ọmọ Israẹli. Aaroni yóò máa orúkọ wọn níwájú Olúwa èjìká rẹ̀ méjèèjì fún ìrántí. 13 Ìwọ yóò ṣe ojú ìdè wúrà, 14 àti okùn ̀wọ̀n méjì ti kìkì wúrà, gẹ́gẹ́ ̀àmùrè o so ̀wọ̀n náà mọ́ ojú ìdè náà.

Ìgbàyà

15 "Ìwọ yóò fi iṣẹ́ ọgbọ́n ṣe ìgbàyà fún ìpinnu iṣẹ́ ọnà gbẹ́nàgbẹ́. Ìwọ yóò ṣe é ̀efodu ti wúrà, ti aṣọ aláró, ti elése àlùkò, ti òdòdó àti ti ̀gbọ̀ olókùn wíwẹ́ dáradára. 16 28.16-28: Ek 39.8-21.ìhà mẹ́rẹ̀̀rin rẹ̀ ṣe déédéó jẹ́ ìwọ̀n ìka kan ìnà àti ìwọ̀n ìka kan ìbú, o ṣe é ìṣẹ́po méjì. 17 Nígbà náà ni ìwọ yóò de òkúta oníyebíye mẹ́rin sára ẹsẹ̀ rẹ̀. ẹsẹ̀ àkọ́kọ́ ni rúbì, topasi àti berili ; 18 ẹsẹ̀ kejì turikuose, emeradi, safire, àti diamọndi; 19 ẹsẹ̀ kẹta, jasiniti, agate, àti ametisiti; 20 ẹsẹ̀ kẹrin, topasi, àti óníkìsì àti jasperi. A ó wọ́n ojú wúrà dìde wọn. 21 Òkúta méjìlá yóò , ̀kọ̀̀kan fún orúkọ àwọn ọmọ Israẹli olúkúlùkù èdìdì àmì pẹ̀orúkọ ẹnìkọ̀̀kan ̀Israẹli méjìlá.

22 "Fún ìgbàyà náà, ìwọ yóò ṣe okùn ̀wọ̀n ti kìkì wúrà, gẹ́gẹ́ ̀àmùrè. 23 Ìwọ yóò ṣe òrùka wúrà méjì fún un, o so wọ́n mọ́ igun méjèèjì ìgbàyà náà. 24 Ìwọ yóò so ̀wọ̀n wúrà méjèèjì mọ́ òrùka igun ìgbàyà náà, 25 àti etí ̀wọ̀n méje ni o so mọ́ ojú ìdè méjèèjì, o fi èjìká ̀efodu náà níwájú. 26 Ìwọ yóò ṣe òrùka wúrà méjì, ìwọ yóò so wọ́n mọ́ igun méjì ìgbàyà kejì ìhà inú ó ti ̀efodu náà. 27 Ìwọ yóò ṣe òrùka wúrà méjì, ìwọ yóò fi wọ́n èjìká ̀efodu méjèèjì ìsàlẹ̀, ìhà iwájú rẹ̀, ó súnmọ́ ojú ìránṣọ náà, lókè onírúurú ọnà ̀̀efodu náà. 28 Wọn yóò so òrùka ìgbàyà mọ́ òrùka ̀efodu pẹ̀̀aláró, pa á pọ̀ mọ́ ìgbànú, a ba à ìgbàyà náà kúrò lára ̀efodu náà.

29 "Nígbàkígbà Aaroni wọ Ibi Mímọ́, òun yóò ru orúkọ àwọn ọmọ Israẹli gbogbo ̀kan rẹ̀ ni ìgbàyà ìpinnu ìrántí nígbà gbogbo níwájú Olúwa. 30 Bákan náà ìwọ yóò mu Urimu àti Tumimu sínú ìgbàyà, wọn ó ọkàn Aaroni nígbàkígbà ó ń wólẹ̀ níwájú Olúwa. Aaroni yóò máa ru ohun ti a ń fi ṣe ìpinnu fún àwọn ọmọ Israẹli ọkàn rẹ̀ nígbà gbogbo níwájú Olúwa.

Àwọn Aṣọ Àlùfáà Mìíràn

31 28.31-34: Ek 39.22-26. "Ìwọ yóò ṣì ṣe aṣọ ìgúnwà ̀efodu náà kìkì aṣọ aláró, 32 pẹ̀ojú ọrùn ó láàrín rẹ̀ fún orí. iṣẹ́ ̀létí rẹ̀ ìṣẹ́i agbádá, ó ba à ya. 33 Ṣe pomegiranate ti aṣọ aláró, ti elése àlùkò àti ti òdòdó ìṣẹ́̀àmùrè náà , pẹ̀ṣaworo wúrà láàrín wọn. 34 Àwọn ṣaworo wúrà àti àwọn pomegiranate ni ó ìṣẹ́̀àmùrè náà . 35 Aaroni gbọdọ̀ máa wọ̀ ́ nígbà o ń ṣiṣẹ́. A ó máa gbọ́ ìró àwọn agogo nígbà ó ń wọ Ibi Mímọ́ níwájú Olúwa àti nígbà ó ń jáde bọ̀, ó ba à .

36 28.36,37: Ek 39.30,31. "Ìwọ yóò ṣe àwo kìkì wúrà, ìwọ yóò fín sára rẹ̀ , fínfín èdìdì àmì .

Mímọ́ Olúwa.

37 Ìwọ yóò fi ̀aláró sára rẹ̀ ìwọ yóò so ó mọ́ fìlà náà; ó níwájú fìlà náà. 38 ó níwájú orí Aaroni, ó máa ru ̀bi ó jẹ mọ́ ̀bùn mímọ́ ti àwọn ọmọ Israẹli ti mímọ́, èyíkéyìí ̀bùn wọn jẹ́. Yóò máa níwájú orí Aaroni nígbà gbogbo, wọn jẹ́ ìtẹ́wọ́gbà fún Olúwa.

39 28.39,40,42: Ek 39.27-29. "Ìwọ yóò fi ̀gbọ̀ dáradára hun ̀àwọ̀tẹ́lẹ̀, ìwọ yóò fi ̀gbọ̀ dáradára ṣe fìlà. Ìwọ yóò fi iṣẹ́ abẹ́rẹ́ ṣe ̀àmùrè. 40 Ìwọ yóò ̀àwọ̀tẹ́lẹ̀, ̀àmùrè àti ìgbàrí fún àwọn ọmọ Aaroni, láti fún wọn ̀ṣọ́ àti ọlá. 41 Lẹ́yìn ìwọ ti fi àwọn aṣọ wọ̀nyí wọ Aaroni arákùnrin rẹ, ìwọ yóò fi wọ àwọn ọmọ rẹ̀ pẹ̀, ìwọ ó ta òróró wọn orí, ìwọ yóò ya wọ́n mímọ́. Ìwọ yóò sọ wọ́n di mímọ́, wọn o máa ṣe iṣẹ́ àlùfáà.

42 "Ìwọ yóò ṣòkòtò ̀gbọ̀ fún wọn, wọn máa fi bo ìhòhò wọn, ó ìbàdí itan. 43 Aaroni àti àwọn ọmọ rẹ̀ gbọdọ̀ wọ̀ wọ́n nígbàkígbà wọ́n wọ àgọ́ àjọ lọ tàbí nígbà wọ́n súnmọ́ pẹpẹ láti ṣiṣẹ́ Ibi Mímọ́ wọn ó ba à dẹ́ṣẹ̀, wọn a .

"Èyí jẹ́ ìlànà láéláé fún Aaroni àti fún irú-ọmọ rẹ̀ lẹ́yìn rẹ̀.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também