Pular para o conteúdo
Publicidade

Eksodu 5

Bíríkì sísun láìsí koríko gbígbẹ

1 Lẹ́yìn náà ni Mose àti Aaroni tọ Farao lọ, wọ́n , "Èyí ni ohun Olúwa, Ọlọ́run Israẹli sọ, Jẹ́ àwọn ènìyàn mi ó lọ, wọn ó ṣe àjọ mi ijù.’ "

2 Farao dáhùn , "Ta ni Olúwa, èmi yóò fi gbọ́rọ̀ i lẹ́nu, èmi yóò fi jẹ́ Israẹli ó lọ? Èmi mọ Olúwa, èmi jẹ́ Israẹli ó lọ."

3 Lẹ́yìn náà ni wọ́n , "Ọlọ́run àwọn Heberu pàdé wa. ìsinsin yìí, jẹ́ a lọ ìrìn ọjọ́ mẹ́ta sínú aginjù láti ẹbọ Olúwa Ọlọ́run wa, Ó ba á fi àjàkálẹ̀-ààrùn tàbí idà wa ."

4 Ṣùgbọ́n ọba Ejibiti sọ , "Mose àti Aaroni, èéṣe ti ̀yin fi àwọn ènìyàn kúrò lẹ́nu iṣẹ́ wọn? padà sẹ́nu iṣẹ́ yín." 5 Nígbà náà ni Farao sọ , "ó àwọn ènìyàn náà ti pọ̀ ì nílẹ̀ yìí ìsinsin yìí, ̀yin ń wọn dúró láti máa iṣẹ́ lọ."

6 ọjọ́ yìí kan náà ni Farao pàṣẹ fún àwọn akóniṣiṣẹ́ àti àwọn ti ń ṣe alábojútó iṣẹ́ lórí àwọn ènìyàn. 7 "̀yin láti pèsè koríko gbígbẹ fún bíríkì sísun mọ́ fún àwọn ènìyàn wọ̀nyí; jẹ́ wọn máa koríko gbígbẹ fún ara wọn. 8 Ṣùgbọ́n jẹ́ wọn ó ṣe iye bíríkì kan náà ì ti àtẹ̀yìnwá, ṣe dín iye rẹ̀ . ̀lẹ ni wọ́n, ìwà ̀lẹ yìí náà wọn pariwo , jẹ́ a lọ, a ẹbọ Ọlọ́run wa.9 iṣẹ́ náà le fún wọn, wọn a le è tẹramọ́ iṣẹ́ wọn, fi ààyè gba irọ́ wọn."

10 ìgbà náà ni àwọn akóniṣiṣẹ́ àti àwọn ń ṣe alábojútó iṣẹ́ jáde tọ̀ wọ́n lọ láti sọ fún àwọn ènìyàn náà , "Èyí ni ohun Farao sọ, Èmi fún un yín ni koríko gbígbẹ mọ́. 11 lọ koríko gbígbẹ ni ibi ti i, ṣùgbọ́n iṣẹ́ yín yóò dínkù.’ " 12 Gbogbo wọn fọ́n káàkiri ni ilẹ̀ Ejibiti láti sa ìdì koríko wọn yóò ì koríko gbígbẹ fún sísun bíríkì. 13 Àwọn akóniṣiṣẹ́ ń ni wọ́n lára, wọ́n , "parí iṣẹ́ ni láti ṣe fún ọjọ́ kan ìgbà ti a ń fún un yin koríko gbígbẹ." 14 Àwọn alábojútó iṣẹ́ àwọn akóniṣiṣẹ́ Farao yàn lára ọmọ Israẹli ni wọn ń , wọn ń béèrè lọ́wọ́ wọn , "Èéṣe ̀yin ṣe iye bíríkì ti ̀yin ń ṣe àná òní i àtẹ̀yìnwá?"

15 Nígbà náà ni àwọn alábojútó iṣẹ́ a yàn lára àwọn ọmọ Israẹli tọ Farao lọ láti lọ bẹ̀bẹ̀ , "Èéṣe ìwọ fi ọwọ́ líle àwa ọmọ ̀dọ̀ rẹ̀ báyìí? 16 Wọn fún àwọn ọmọ ̀dọ̀ rẹ̀ ni koríko gbígbẹ, síbẹ̀ wọn sọ fún wa , ṣe bíríkì!Wọ́n na àwọn ọmọ ̀dọ̀ rẹ, ṣùgbọ́n ̀bi náà láti ̀dọ̀ àwọn ènìyàn rẹ."

17 Farao dáhùn , "̀lẹ ni yín, ̀lẹ! Èyí ni ó ̀yin máa sọ ìgbà gbogbo , jẹ́ a lọ, a ẹbọ Olúwa.18 Nísinsin yìí padà lọ ẹnu iṣẹ́ yín, a fún un yín ni koríko gbígbẹ, síbẹ̀ gbọdọ̀ ṣe iye bíríkì ó yẹ ṣe."

19 Àwọn ọmọ Israẹli ó jẹ́ alábojútó iṣẹ́ mọ̀ dájú àwọn ti nínú wàhálà ńlá ìgbà a sọ fún wọn , "láti dín iye bíríkì ń ṣe ni ojoojúmọ́ ." 20 ìgbà wọ́n kúrò ni ̀dọ̀ Farao wọ́n Mose àti Aaroni ó dúró láti pàdé wọn. 21 Wọn , "Olúwa ó yín, ó ṣe ìdájọ́! ̀yin ti wa dàbí òórùn búburú fún Farao àti àwọn òṣìṣẹ́ rẹ̀, ti fún wọn ni idà láti fi pa ."

Ọlọ́run ṣe ìlérí ìgbàsílẹ̀ fún Israẹli

22 Mose padà tọ Olúwa lọ, ó , "Olúwa, èéṣe ìwọ fi ìyọnu orí àwọn ènìyàn wọ̀nyí? Ṣe torí èyí ni ìwọ fi rán mi? 23 Láti ìgbà ti mo ti tọ Farao lọ láti a sọ̀rọ̀ ni orúkọ rẹ ni ó ti ìyọnu orí àwọn ènìyàn wọ̀nyí, bẹ́̀ ni ìwọ gba àwọn ènìyàn rẹ sílẹ̀ rárá."

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também