Pular para o conteúdo
Publicidade

Gẹnẹsisi 32

Jakọbu gbáradì láti pàdé Esau

1 Jakọbu ń ̀tirẹ̀ lọ, àwọn angẹli Ọlọ́run pàdé rẹ̀. 2 Nígbà Jakọbu wọn, ó , "Àgọ́ Ọlọ́run ni èyí!" Ó pe orúkọ ibẹ̀ ni Mahanaimu.

3 Jakọbu rán àwọn oníṣẹ́ ṣáájú ara rẹ̀ Esau arákùnrin rẹ̀ ni ilẹ̀ Seiri orílẹ̀-èdè Edomu. 4 Ó pàṣẹ fún wọn , "Èyí ni ̀yin yóò fún Esau olúwa mi, Jakọbu ìránṣẹ́ rẹ̀ , Mo ti ṣe àtìpó lọ́dọ̀ Labani títí ó fi di àsìkò yìí. 5 Mo màlúù, kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́, àgùntàn àti ewúrẹ́. Mo tún ni àwọn ìránṣẹ́kùnrin àti ìránṣẹ́bìnrin. Mo ń ránṣẹ́ yìí olúwa mi èmi le è ojúrere rẹ.’ "

6 Nígbà àwọn ìránṣẹ́ náà padà tọ Jakọbu , wọ́n "Esau arákùnrin rẹ ti múra láti pàdé rẹ pẹ̀irinwó (400) ọkùnrin."

7 Pẹ̀ìbẹ̀àti ìbànújẹ́ ni Jakọbu fi pín àwọn ènìyàn ó lọ́dọ̀ rẹ̀ ìpín méjì, ó pín àwọn ẹran ̀sìn, agbo ẹran àti ìbákasẹ bẹ́̀ pẹ̀. 8 Nítorí ó ó nínú rẹ̀ , "Esau kọjú ogun ìpín kan, ìpín kejì yóò àsálà."

9 Nígbà náà ni Jakọbu gbàdúrà pe, "Ọlọ́run Abrahamu baba mi, àti Ọlọ́run Isaaki baba mi, Olúwa ó fún mi , Padà orílẹ̀-èdè rẹ àti sọ́dọ̀ àwọn ìbátan rẹ, èmi yóò ṣe ́ rere,10 èmi tilẹ̀ yẹ fún àánú àti òtítọ́ o ń fihàn fún ìránṣẹ́ rẹ. Nítorí , kìkì ̀mi ni mo mu kúrò ni ilé kọjá Jordani yìí, ṣùgbọ́n nísinsin yìí, èmi ti di ẹgbẹ́ méjì. 11 Jọ̀wọ́ Olúwa gbà lọ́wọ́ Esau arákùnrin mi, nítorí ̀ń yóò dojú ìjà kọ àti àwọn ìyàwó pẹ̀àwọn ọmọ mi. 12 32.12: Gẹ 22.17.Ṣùgbọ́n ìwọ ti ṣèlérí , Èmi yóò gbilẹ̀, èmi yóò àwọn ìran rẹ í yanrìn òkun ẹnikẹ́ni le è .’ "

13 Ó lo òru ọjọ́ náà níbẹ̀. Ó ̀bùn fún Esau arákùnrin rẹ̀ nínú ohun ìní rẹ̀. 14 Igba ewúrẹ́, ogún òbúkọ, igba àgùntàn, ogún àgbò, 15 ọgbọ̀n abo ìbákasẹ pẹ̀ọmọ wọn, ogójì abo màlúù àti akọ màlúù mẹ́wàá, ogún abo kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ àti akọ kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ mẹ́wàá. 16 Ó fi wọ́n àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀ lọ́wọ́ ̀wọ̀̀wọ́, ó fún wọn , "lọ ṣáájú mi, jẹ́ àlàfo láàrín ̀wọ́ agbo ẹran kọ̀̀kan èkejì."

17 Ó pàṣẹ fún èyí ó ṣáájú , "Nígbà arákùnrin mi Esau pàdé rẹ ó béèrè ẹni ìwọ í ṣe àti ibi ìwọ ń lọ àti ẹni ó ni agbo ẹran ó lọ́dọ̀ rẹ, 18 nígbà náà ni ìwọ yóò , Ti ìránṣẹ́ rẹ Jakọbu ni wọ́n. ̀bùn ni ó fi wọ́n ṣe fún Esau olúwa mi, òun pàápàá ń bọ̀ lẹ́yìn wa.’ "

19 Jakọbu pàṣẹ bẹ́̀ gẹ́gẹ́ fún ̀wọ́ kejì àti ̀kẹta àti àwọn tókù ó tẹ̀agbo ẹran , "Ohun kan ṣoṣo yìí náà ni sọ fún Esau nígbà pàdé rẹ̀. 20 i dájú , sọ fún un , Jakọbu ìránṣẹ́ rẹ̀ ń bọ̀ lẹ́yìn wa.’ " Èrò Jakọbu ni láti fi àwọn ̀bùn wọ̀nyí tu Esau lójú bóyá inú Esau yóò dùn òun nígbà àwọn pàdé. 21 Nítorí náà ̀bùn Jakọbu ṣáájú rẹ̀ lọ, Jakọbu pàápàá lo òru ọjọ́ náà nínú àgọ́.

Jakọbu Ọlọ́run ja ìjàkadì

22 Ó dìde òru ọjọ́ náà, ó àwọn aya rẹ̀ méjèèjì, àwọn ìránṣẹ́bìnrin rẹ̀ méjèèjì, àti àwọn ọmọkùnrin rẹ̀ mọ́kọ̀̀kànlá, wọ́n kọjá ìwọdò Jabbok. 23 Lẹ́yìn ìgbà ó ti rán wọn kọjá odò tán òkè odò, ó rán àwọn ohun ìní rẹ̀ kọjá pẹ̀. 24 32.24-26: Ho 12.3,4.Ó ku Jakọbu nìkan, ọkùnrin kan a ja ìjàkadì títí ó fi di àfẹ̀mọ́júmọ́. 25 Ṣùgbọ́n nígbà ọkùnrin náà i òun le borí Jakọbu, ó fọwọ́ kàn án ̀́kán ibi eegun itan ti bẹ̀rẹ̀, egungun náà yẹ̀ kúrò lórí ike, ó ti ń ja ìjàkadì. 26 Nígbà náà ni ọkùnrin náà fún un , "Jẹ́ ń máa lọ, nítorí ojúmọ́ ti mọ́."

Ṣùgbọ́n Jakọbu a lóhùn , "Èmi jẹ́ o lọ, àyàfi o súre fún mi."

27 Ọkùnrin náà béèrè orúkọ rẹ̀.

Ó fún un , "Jakọbu ni òun ń jẹ́."

28 32.28: Gẹ 35.10. Nígbà náà ni ọkùnrin náà , "Orúkọ rẹ yóò jẹ́ Jakọbu mọ́ ṣe Israẹli, nítorí ìwọ ti Ọlọ́run àti ènìyàn , o borí."

29 32.29: On 13.17,18. Jakọbu bẹ ọkùnrin náà , "Sọ orúkọ rẹ fún mi."

Ṣùgbọ́n ọkùnrin náà à dáhùn , "Èéṣe o ń béèrè orúkọ mi?" Lẹ́yìn náà ó súre fún Jakọbu níbẹ̀.

30 Jakọbu pe orúkọ ibẹ̀ Penieli , "Mo Ọlọ́run ojúkojú, síbẹ̀ a ̀mi ."

31 ó ti ń kọjá Penieli, oòrùn ràn a, ó ń tiro nítorí itan rẹ̀. 32 Ìdí nìyí àwọn ọmọ Israẹli í fi í jẹ iṣan ó ̀́kán ibi eegun itan ti bẹ̀rẹ̀ títí di òní olónìí, nítorí níbi iṣan náà ni a ti fọwọ́ kan ibi egungun itan Jakọbu ti bẹ̀rẹ̀.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também