Pular para o conteúdo
Publicidade

Gẹnẹsisi 36

Àwọn ìránṣẹ́ Esau

1 Wọ̀nyí ni ìran Esau, ẹni a ń Edomu.

2 36.2: Gẹ 26.34; 28.9. Nínú àwọn ọmọbìnrin Kenaani ni Esau ti fẹ́ àwọn ìyàwó rẹ̀: Adah ọmọbìnrin Eloni ará Hiti àti Oholibama, ọmọbìnrin Ana, ọmọ ọmọ Sibeoni ará Hifi. 3 36.3: Gẹ 28.9.Ó tún fẹ́ Basemati ọmọ Iṣmaeli arábìnrin Nebaioti.

4 Adah Elifasi fún Esau, Basemati Reueli, 5 Oholibama pẹ̀Jeuṣi, Jalamu, àti Kora. Àwọn wọ̀nyí ni ọmọ Esau Kenaani.

6 Esau àwọn aya rẹ̀, àwọn ọmọkùnrin rẹ̀, àwọn ọmọbìnrin rẹ̀ àti gbogbo àwọn ará ilé rẹ̀, àwọn ohun ̀sìn rẹ̀ àti àwọn ẹran ̀sìn mìíràn àti gbogbo ohun ìní mìíràn ó , ni Kenaani, ó lọ ilẹ̀ mìíràn, jìnà ibi Jakọbu arákùnrin rẹ̀ . 7 Ohun ìní wọn pọ̀ ju èyí àwọn méjèèjì máa gbé ojú kan lọ. Ilẹ̀ wọ́n le gba àwọn méjèèjì nítorí àwọn ohun ̀sìn wọn. 8 Báyìí ni Esau (a tún mọ̀ Edomu) tẹ̀àwọn orílẹ̀-èdè olókè Seiri.

9 Èyí ni ìran Esau baba àwọn ará Edomu àwọn orílẹ̀-èdè olókè Seiri.

10 Wọ̀nyí ni orúkọ àwọn ọmọ Esau:

Elifasi ọmọ Adah aya Esau àti Reueli, ọmọ Basemati í ṣe aya Esau pẹ̀.

11 Àwọn ọmọ Elifasi ni ìwọ̀nyí:

Temani, Omari, Sefi, Gatamu, àti Kenasi. 12 Elifasi ọmọ Esau tún àlè a ń Timna pẹ̀, òun Amaleki fún un. Wọ̀nyí ni àwọn ọmọ ọmọ Adah aya Esau.

13 Àwọn ọmọ Reueli:

Nahati, Sera, Ṣamma àti Missa. Àwọn ni ọmọ ọmọ Basemati aya Esau.

14 Wọ̀nyí ni àwọn ọmọ Oholibama ọmọbìnrin Ana ọmọ ọmọ Sibeoni: ó fún Esau:

Jeuṣi, Jalamu àti Kora.

15 Àwọn wọ̀nyí ni olórí nínú àwọn ọmọ Esau:

àwọn ọmọ Elifasi, àkọ́Esau,

Temani, Omari, Sefi, Kenasi, 16 Kora, Gatamu àti Amaleki. Àwọn wọ̀nyí jẹ́ olórí ìdílé ó ti ̀dọ̀ Elifasi Edomu , wọ́n jẹ́ ọmọ ọmọ Adah.

17 Wọ̀nyí ni àwọn ọmọ Esau, ọmọ Rueli:

Nahati olórí, Sera olórí, Ṣamma olórí, Missa olórí. Àwọn wọ̀nyí jẹ́ olórí ìdílé ó ti ̀dọ̀ Reueli jáde Edomu. Ọmọ ọmọ Basemati aya Esau ni wọ́n jẹ́.

18 Àwọn ọmọ Oholibama aya Esau:

Jeuṣi, Jalamu, àti Kora, àwọn wọ̀nyí jẹ́ olórí ìdílé ó ti ̀dọ̀ Oholibama ọmọ Ana, ìyàwó Esau .

19 Àwọn wọ̀nyí ni ọmọ Esau (ti o túmọ̀ Edomu). Àwọn wọ̀nyí ni olórí wọn.

20 36.20-28: 1Ki 1.38-42. Wọ̀nyí ni àwọn ọmọ Seiri ará Hori ó ń gbé ilẹ̀ náà:

Lotani, Ṣobali, Sibeoni, Ana, 21 Diṣoni, Eseri, àti Diṣani, àwọn wọ̀nyí olórí ènìyàn Hori, àwọn ọmọ Seiri ni ilẹ̀ Edomu.

22 Àwọn ọmọ Lotani:

Hori àti Homamu: Timna ni arábìnrin Lotani.

23 Àwọn ọmọ Ṣobali:

Alifani, Manahati, Ebali, Ṣefo àti Onamu.

24 Àwọn ọmọ Sibeoni:

Aiah àti Ana. Èyí ni Ana ó ìsun omi gbígbóná inú aginjù ó ti ń da àwọn kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ Ṣebeoni baba rẹ̀.

25 Wọ̀nyí ni àwọn ọmọ Ana:

Diṣoni àti Oholibama ọmọbìnrin Ana.

26 Àwọn ọmọ Diṣoni ni:

Hemdani, Eṣbani, Itrani àti Kerani.

27 Àwọn ọmọ Eseri:

Bilhani, Saafani àti Akani.

28 Àwọn ọmọ Diṣani ni:

Usi àti Arani.

29 Àwọn wọ̀nyí ni olórí ìdílé Hori:

Lotani, Ṣobali, Sibeoni, Ana, 30 Diṣoni Eseri, àti Diṣani.

Àwọn ni olórí ìdílé àwọn ará Hori gẹ́gẹ́ ìpín wọn ilẹ̀ Seiri.

Àwọn aláṣẹ Edomu

31 36.31-43: 1Ki 1.43-53. Àwọn wọ̀nyí ni ọba ó jẹ Edomu ó di ọba kankan jẹ lórí Israẹli:

32 Bela ọmọ Beori jẹ Edomu. Orúkọ ìlú rẹ̀ ni Dinhaba.

33 Nígbà Bela , Jobabu ọmọ Sera ti Bosra jẹ ọba ipò rẹ̀.

34 Nígbà Jobabu , Huṣamu láti ilẹ̀ Temani jẹ ọba ipò rẹ̀.

35 Nígbà Huṣamu , Hadadi ọmọ Bedadi ó kọlu Midiani ìgbẹ́ Moabu, ó jẹ ọba ipò rẹ̀. Orúkọ ìlú rẹ̀ ni Afiti.

36 Nígbà Hadadi , Samla láti Masreka, ó jẹ ọba ipò rẹ̀.

37 Samla , Saulu ti Rehoboti, létí odò jẹ ọba ipò rẹ̀.

38 Nígbà Saulu , Baali-Hanani ọmọ Akbori jẹ ọba ipò rẹ̀.

39 Nígbà Baali-Hanani ọmọ Akbori , Hadadi ni ó jẹ ọba ipò rẹ̀. Orúkọ ìlú rẹ̀ ni Pau, orúkọ ìyàwó ni Mehetabeeli ọmọbìnrin Matiredi, ọmọbìnrin Mesahabu.

40 Àwọn wọ̀nyí ni orúkọ àwọn baálẹ̀ ó ti ̀dọ̀ Esau jáde , orúkọ ìdílé wọn, ìpínlẹ̀ wọn ti :

baálẹ̀ Timna, baálẹ̀ Alfa, baálẹ̀ Jeteti.

41 Baálẹ̀ Oholibama, baálẹ̀ Ela, baálẹ̀ Pinoni,

42 baálẹ̀ Kenasi, baálẹ̀ Temani, baálẹ̀ Mibsari,

43 Magdieli, àti Iramu.

Àwọn wọ̀nyí ni baálẹ̀ Edomu, gẹ́gẹ́ wọn ti tẹ̀ilẹ̀ wọ́n gbà.

Èyí ni Esau baba àwọn ará Edomu.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também