Pular para o conteúdo
Publicidade

Gẹnẹsisi 5

Ìran Adamu títí ìran Noa

1 5.1,2: Gẹ 1.27,28; Mt 19.4; Mk 10.6. Èyí ni àkọsílẹ̀ ìran Adamu.

Nígbà Ọlọ́run ènìyàn, àwòrán Ọlọ́run ni ó a. 2 Àti akọ àti abo ni Ó wọn, ó súre fún wọn, ó pe orúkọ wọ́n Adamu ọjọ́ ó wọn.

3 Nígbà Adamu di ẹni àádóje ọdún, ó ọmọkùnrin kan ó jọ ́, ó jẹ́ àwòrán ara rẹ̀, ó pe orúkọ rẹ̀ Seti. 4 Ọjọ́ Adamu, lẹ́yìn ìgbà ó Seti, jẹ́ ẹgbẹ̀rin (800) ọdún, ó àwọn ọmọkùnrin àti ọmọbìnrin. 5 Àpapọ̀ ọdún Adamu gbé orí ilẹ̀ jẹ́ ̀́dẹ́gbẹ̀rún ọdún ó ọgbọ̀n (930), ó .

6 Nígbà Seti àrùnlélọ́gọ́rùn-ún ọdún, ó Enoṣi. 7 Lẹ́yìn ìgbà ó Enoṣi, Seti gbé fún ẹgbẹ̀rin ọdún ó méje (807), ó àwọn; ọmọkùnrin àti ọmọbìnrin. 8 Àpapọ̀ ọdún Seti jẹ́ ̀́dẹ́gbẹ̀rún ọdún ó méjìlá (912), ó .

9 Nígbà Enoṣi di ẹni àádọ́rùn-ún ọdún ni ó Kenani. 10 Lẹ́yìn ó Kenani, Enoṣi láààyè fún ẹgbẹ̀rin ọdún ó mẹ́̀́dógún (815), ó àwọn ọkùnrin àti obìnrin. 11 Àpapọ̀ ọdún Enoṣi jẹ́ ̀́dẹ́gbẹ̀rún ọdún ó márùn-ún (905), ó .

12 Nígbà Kenani di àádọ́rin ọdún ni ó Mahalaleli. 13 Lẹ́yìn ó Mahalaleli, Kenani láààyè fún òjìlélẹ́gbẹ̀rin ọdún (840), ó àwọn ọmọkùnrin àti ọmọbìnrin. 14 Àpapọ̀ ọjọ́ Kenani jẹ́ ̀́dẹ́gbẹ̀rún ọdún ó mẹ́wàá (910), ó .

15 Nígbà Mahalaleli ọmọ àrùnlélọ́gọ́ta ọdún ni ó Jaredi. 16 Mahalaleli gbé fún ẹgbẹ̀rin ọdún ó ọgbọ̀n (830) lẹ́yìn ìgbà ó Jaredi, ó àwọn ọmọkùnrin àti ọmọbìnrin. 17 Àpapọ̀ iye ọdún Mahalaleli jẹ́ ̀́dẹ́gbẹ̀rún ọdún ó dín márùn-ún (895), ó .

18 Nígbà Jaredi ọmọ ọgọ́jọ ọdún ó méjì ni ó Enoku. 19 Lẹ́yìn èyí, Jaredi láààyè fún ẹgbẹ̀rin (800) ọdún Enoku àwọn ọmọkùnrin àti ọmọbìnrin. 20 Àpapọ̀ ọdún Jaredi jẹ́ ẹgbẹ̀rún dín méjìdínlógójì (962), ó .

21 Nígbà Enoku ọmọ ọgọ́ta ọdún ó márùn ni ó Metusela. 22 Lẹ́yìn ó Metusela, Enoku Ọlọ́run rìn ̀́dúnrún (300) ọdún, ó àwọn ọmọkùnrin àti ọmọbìnrin. 23 Àpapọ̀ ọjọ́ Enoku jẹ́ irinwó ọdún dín márùndínlógójì (365). 24 5.24: Hb 11.5; Jd 14.Enoku Ọlọ́run rìn; a i mọ́ nítorí Ọlọ́run un lọ.

25 Nígbà Metusela igba ọdún dín mẹ́tàlá o Lameki. 26 Lẹ́yìn èyí Metusela láààyè fún ẹgbẹ̀rin ọdún dín méjìdínlógún (782), lẹ́yìn ìgbà ó Lameki, ó àwọn ọmọkùnrin àti ọmọbìnrin. 27 Àpapọ̀ ọdún Metusela jẹ́ ẹgbẹ̀rún ọdún dín mọ́kànlélọ́gbọ̀n (969), ó .

28 Nígbà Lameki ọdún méjìlélọ́gọ́sàn án ni ó ọmọkùnrin kan. 29 Ó pe orúkọ rẹ̀ Noa, ó , "Eléyìí ni yóò nínú ni iṣẹ́ àti làálàá ọwọ́ wa, nítorí ilẹ̀ Olúwa ti fi gégùn ún." 30 Lẹ́yìn ó Noa, Lameki gbé fún ẹgbẹ̀ta ọdún dín márùn-ún (595), ó àwọn ọmọkùnrin àti ọmọbìnrin. 31 Àpapọ̀ ọdún Lameki jẹ́ ẹgbẹ̀rin ọdún dín mẹ́tàlélógún (777), ó .

32 Lẹ́yìn Noa ọmọ ̀́dẹ́gbẹ̀ta (500) ọdún ni ó Ṣemu, Hamu àti Jafeti.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também