Pular para o conteúdo
Publicidade

Gẹnẹsisi 34

Dina àti àwọn ará Ṣekemu

1 ọjọ́ kan, Dina ọmọbìnrin Lea fún Jakọbu jáde lọ bẹ àwọn ọmọbìnrin ilẹ̀ náà . 2 Nígbà Ṣekemu ọmọ ọba Hamori ará Hifi i, ó un, ó fi ipá a lo pọ̀. 3 Ọkàn rẹ Dina ọmọ Jakọbu gan an, ó fẹ́ràn rẹ̀ ó ọmọbìnrin náà sọ̀rọ̀ ìfẹ́. 4 Ṣekemu fún Hamori baba rẹ̀ , "Fẹ́ ọmọbìnrin yìí fún mi aya."

5 Nígbà Jakọbu gbọ́ ohun ó ṣẹlẹ̀ a fi ipá Dina ọmọbìnrin òun ògo jẹ́, ṣùgbọ́n àwọn ọmọ rẹ̀ nínú pápá níbi wọ́n ti ń daran nítorí náà ó sùúrù títí wọ́n fi .

6 Hamori baba Ṣekemu jáde láti Jakọbu sọ̀rọ̀. 7 Àwọn ọmọ Jakọbu ti oko , wọ́n gbọ́ ohun ó ṣẹlẹ̀ inú wọn bàjẹ́, ó ń wọn nínú gidigidi, nítorí ó ṣe ohun búburú Israẹli, ti ó ọmọbìnrin ọmọ Jakọbu lòpọ̀—irú ohun yẹ ó ṣẹlẹ̀ rárá.

8 Hamori wọn sọ̀rọ̀ , "Ọkàn ọmọ mi Ṣekemu ọmọ rẹ. Jọ̀wọ́ fi fún un gẹ́gẹ́ aya. 9 jẹ́ a máa ṣe ìgbéyàwó láàrín ara wa, àwọn ọmọ yín máa fẹ́ àwọn ọmọ wa. 10 máa gbé láàrín wa, ibikíbi ó tẹ́ yín lọ́rùn láàrín wa ni gbé, máa ṣe òwò yín ọrọ̀ jọ fún ara yín."

11 Ṣekemu fún baba àti arákùnrin Dina , "jọ̀wọ́, jẹ́ n ojúrere yín, èmi yóò fún yín ohunkóhun ̀yin fẹ́ gbà. 12 Iyekíye owó orí rẹ̀ jẹ́ àti ̀bùn gbogbo fẹ́, ó ti ó pọ̀ , èmi yóò san án, à jẹ́ ń fi ọmọ náà ṣe aya."

13 Àwọn ọmọ Jakọbu fi ̀tàn Ṣekemu àti Hamori baba rẹ̀ lóhùn, wọ́n , nítorí ó ti ba ògo Dina arábìnrin wọn jẹ́. 14 Wọ́n fún wọn , "Àwa le ṣe nǹkan yìí láti fi arábìnrin wa fún aláìkọlà, nítorí àbùkù ni èyí yóò jẹ́ fún wa. 15 Àwa yóò fi ara mọ́ ọn ̀yin yóò gbà láti dàbí i tiwa, ̀yin pẹ̀yóò kọ gbogbo ọkùnrin yín ilà. 16 Nígbà náà ni àwa yóò le máa fún yín ọmọ wa, àwa náà yóò máa fẹ́ yín. A ó máa gbé láàrín yín, a ó di ara kan pẹ̀yín. 17 Ṣùgbọ́n ̀yin kọ̀ láti kọlà, àwa yóò arábìnrin wa, á ó máa lọ."

18 Àbá náà dùn mọ́ Hamori àti Ṣekemu ọmọ rẹ̀. 19 ̀dọ́mọkùnrin náà, ẹni ó jẹ́ ẹni iyì jùlọ ilé baba rẹ̀, jáfara láti ṣe ohun wọ́n . Nítorí ó fẹ́ràn ọmọbìnrin Jakọbu. 20 Hamori àti Ṣekemu ọmọ rẹ̀ ẹnu ibodè ìlú náà wọn àwọn ará ìlú náà sọ̀rọ̀. 21 , "Ìwà àwọn ọkùnrin wọ̀nyí dára, jẹ́ wọn máa gbé àárín wa, wọn máa ṣòwò, ilẹ̀ kúkú rẹpẹtẹ gba ààyè dáradára. A fẹ́ àwọn ọmọ wọ́n, ki wọn fẹ́ tiwa pẹ̀. 22 Ṣùgbọ́n kín kan ni a ṣe wọn gbà láti gbé pẹ̀wa, ìyẹn ni àwọn ọkùnrin wa yóò kọlà i tiwọn. 23 Ṣe àwọn ẹran wọn àti ẹrú wọn àti àwọn ohun ̀sìn wọn ni yóò di tiwa a gbà bẹ́̀, wọn yóò máa gbé ni àárín wa."

24 Gbogbo àwọn ọkùnrin ń jáde ẹnu-bodè ìlú náà gbọ́ ti Hamori àti Ṣekemu ọmọ rẹ̀. Gbogbo ọkùnrin ìlú náà kọlà.

25 Lẹ́yìn ọjọ́ kẹta, nígbà gbogbo wọn nínú ìrora. Àwọn ọmọ Jakọbu méjì, Simeoni àti Lefi ó jẹ́ ̀gbọ́n fún Dina, idà wọn pẹ̀ìgboyà, wọ́n pa gbogbo ọkùnrin ìlú náà. 26 Wọ́n fi idà pa Hamori àti Ṣekemu ọmọ rẹ̀, wọ́n Dina kúrò ilé wọn, wọ́n jáde. 27 Àwọn ọmọ Jakọbu wọlé àwọn a pa, wọ́n ẹrù ìlú a ti ba ògo arábìnrin wọn jẹ́. 28 Wọ́n màlúù wọn àti agbo ẹran wọn àti kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́, àti ohun gbogbo ó nínú ìlú àti oko. 29 Gbogbo ọrọ̀ wọn, gbogbo obìnrin ìlú àti àwọn ọmọ wẹẹrẹ pátápátá ni wọ́n . Wọ́n gbogbo ohun ó nínú ilé wọn ìkógun.

30 Nígbà náà ni Jakọbu fún Simeoni àti Lefi , "̀yin ti ìyọnu mi nípa sísọ di olóòórùn láàrín ará Kenaani àti Peresi, ó ń gbé ilẹ̀ yìí. Àwa pọ̀, wọn parapọ̀ ṣígun wa, gbogbo wa pátápátá ni wọn yóò parun."

31 Ṣùgbọ́n wọ́n dáhùn , "Ǹjẹ́ ó yẹ ó ṣe arábìnrin wa panṣágà?"

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também