Pular para o conteúdo
Publicidade

Gẹnẹsisi 42

Àwọn arákùnrin Josẹfu lọ Ejibiti

1 Nígbà Jakọbu mọ̀ ọkà Ejibiti, ó fún àwọn ọmọ rẹ̀ ọkùnrin , "Èéṣe ń wo ara yín lásán?" 2 42.2: Ap 7.12."Mo gbọ́ ọkà ilẹ̀ Ejibiti. sọ̀kalẹ̀ lọ ibẹ̀ fún wa, a ba à ."

3 Nígbà náà ni mẹ́wàá nínú àwọn arákùnrin Josẹfu sọ̀kalẹ̀ lọ Ejibiti láti ra ọkà. 4 Ṣùgbọ́n Jakọbu rán Benjamini àbúrò Josẹfu lọ pẹ̀wọn nítorí ̀ń á aburú ba à ṣẹlẹ̀ i. 5 42.5: Ap 7.11.Nítorí náà, àwọn ọmọ Israẹli lára àwọn lọ Ejibiti lọ ra oúnjẹ nítorí ìyàn náà ni ilẹ̀ Kenaani pẹ̀.

6 Nísinsin yìí, Josẹfu ni alábojútó fún gbogbo ilẹ̀ Ejibiti, òun ni ó ń bojútó ọkà títà fún gbogbo ènìyàn ìlú náà. Nítorí náà nígbà àwọn arákùnrin Josẹfu , wọ́n tẹríba, wọ́n foríbalẹ̀ fún Josẹfu. 7 Lọ́gán Josẹfu ti àwọn arákùnrin rẹ̀ ni ó ti wọn mọ̀, ṣùgbọ́n ó ṣe i mọ̀ wọ́n, ó sọ̀rọ̀ líle wọn. Ó béèrè , "Níbo ni ti ?"

Wọ́n dáhùn , "Láti ilẹ̀ Kenaani ni a ti ra oúnjẹ."

8 ó tilẹ̀ jẹ́ , Josẹfu mọ àwọn arákùnrin rẹ̀, síbẹ̀ àwọn arákùnrin rẹ̀ mọ̀ ́n. 9 42.9: Gẹ 37.5-10.Nígbà náà ni ó rántí àlá rẹ̀ ó wọn, ó fún wọn , "Amí42.9 tí ó túmọ̀ sí, Ayọ́lẹ̀wò ni yín, láti wo àṣírí ilẹ̀ wa ni."

10 Wọ́n dáhùn , "Bẹ́̀ kọ́ olúwa wa, àwọn ìránṣẹ́ rẹ láti ra oúnjẹ ni. 11 Ọmọ baba ni , olóòtítọ́ ènìyàn ni pẹ̀, àwa í ṣe ayọ́lẹ̀."

12 Ó fún wọn , "Rárá! láti wo àṣírí ilẹ̀ wa ni."

13 Ṣùgbọ́n wọ́n tún dáhùn , "Arákùnrin méjìlá ni àwa ìránṣẹ́ rẹ, ọmọ baba kan náà, ó ń gbé ilẹ̀ Kenaani. Èyí ó jẹ́ àbíkẹ́yìn wa ń bẹ lọ́dọ̀ baba wa, ̀kan ti ."

14 Josẹfu fún wọn , "mo ti fún un yín náà ni, Ayọ́lẹ̀ni yín! 15 Èyí ni a ó fi dán an yín , èmi búra , níwọ̀n ìgbà Farao láààyè, yóò kúrò níbí, àyàfi arákùnrin yín kan tókù ibí. 16 rán ̀kan nínú yín lọ láti arákùnrin yín , àwa yóò fi ̀yin tókù pamọ́ sínú túbú, àwa ba à mọ bóyá òtítọ́ ni ̀yin ń . Ṣùgbọ́n ó jẹ́ irọ́ ni ̀yin ń pa, òtítọ́ Farao ti ń bẹ láààyè ayọ́lẹ̀ni yín!" 17 Ó fi gbogbo wọn sínú túbú fún ọjọ́ mẹ́ta.

18 ọjọ́ kẹta, Josẹfu fún wọn , "Èyí ni ̀yin yóò ṣe ̀yin ba à le nítorí mo bẹ̀Ọlọ́run. 19 ó jẹ́ olóòtítọ́ ènìyàn ni yín, jẹ́ ̀kan nínú yín dúró ni túbú ìhín, nígbà àwọn yòókù yín yóò gbé ọkà lọ fún àwọn ará ilé e yín ebi ń pa. 20 Ṣùgbọ́n gbọdọ̀ arákùnrin ó jẹ́ àbíkẹ́yìn yín , n ba à le mọ òtítọ́ ohun ti ń , ba à ." Wọn gbà láti ṣe èyí.

21 Wọ́n ń sọ ́ láàrín ara wọn , "Àwa jẹ̀bi nítòótọ́ nípa ti arákùnrin wa. A ìbànújẹ́ ọkàn rẹ̀ nígbà ó ń bẹ̀ nítorí ̀rẹ̀, ṣùgbọ́n a gbẹ́bẹ̀, nítorí náà ni ìdààmú yìí fi wa."

22 42.22: Gẹ 37.21,22. Reubeni wọn ohùn , "Èmi fún yín se ṣẹ̀ ọmọdékùnrin náà? Ṣùgbọ́n gbọ́! Ṣùgbọ́n nísinsin yìí a ń béèrè ̀jẹ̀ rẹ̀ lọ́wọ́ wa." 23 Wọn mọ̀ , Josẹfu ń gbọ́ wọn àgbọ́nítorí ògbufọ̀ ni ó ń tẹ́lẹ̀.

24 Ó yípadà kúrò lọ́dọ̀ wọn, ó bẹ̀rẹ̀ sọkún. Ó tún padà wọn, ó bẹ̀rẹ̀ sọ̀rọ̀. Ó Simeoni kúrò láàrín wọn, ó é ojú wọn.

25 Josẹfu pàṣẹ wọn bu ọkà kún inú àpò wọn, wọn owó ẹnìkọ̀̀kan padà sínú àpò rẹ̀, wọn fún wọn ohun wọn yóò nírín-àjò wọn padà sílé. Lẹ́yìn ìgbà a ti ṣe èyí fún wọn, 26 wọn gbé ẹrù wọn kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́, wọn padà lọ ilé.

27 Níbi wọ́n ti dúró láti sùn lóru ọjọ́ náà, ̀kan nínú wọn àpò rẹ̀ láti oúnjẹ fún kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ rẹ̀, ó owó rẹ̀ ẹnu àpò rẹ̀. 28 Ó fún àwọn arákùnrin rẹ̀ , "a ti owó mi padà, òun nìyí ẹnu àpò mi."

̀wọ́n, wọ́n ń gbọ̀n, wọ́n , "Èwo nìyí Ọlọ́run ṣe wa yìí."

29 Nígbà wọ́n padà ̀dọ̀ Jakọbu baba wọn ilẹ̀ Kenaani, wọ́n ròyìn gbogbo ohun ó ṣẹlẹ̀ fún un , 30 "Ọkùnrin náà í ṣe alábojútó ilẹ̀ náà, sọ̀rọ̀ líle wa, ó fi ̀sùn kàn a yọ́ ilẹ̀ náà ni. 31 Ṣùgbọ́n, a fún un , Rárá o, olóòtítọ́ ènìyàn ni , a í ṣe ayọ́lẹ̀. 32 Arákùnrin méjìlá ni , ọmọ baba kan náà, ̀kan ti , èyí ó jẹ́ àbíkẹ́yìn lọ́dọ̀ baba wa ni ilẹ̀ Kenaani.

33 "Nígbà náà ni ọkùnrin ó jẹ́ alábojútó ilẹ̀ náà fún wa , Báyìí ni n ó ṣe mọ̀ bóyá olóòtítọ́ ènìyàn ni yín, fi ̀kan nínú àwọn arákùnrin yín sílẹ̀ níbí, pẹ̀mi, oúnjẹ lọ fún àwọn ará ilé yín ebi ń pa lọ, lọ́wọ́ ìyàn. 34 Ṣùgbọ́n arákùnrin yín ó kéré jùlọ fún mi n le mọ̀ dájúdájú í ṣe ayọ́lẹ̀ṣe ènìyàn tòótọ́. Nígbà náà ni n ó arákùnrin yín padà fún un yín, lẹ́yìn náà le máa ṣe òwò ó ti yín ilẹ̀ yìí.’ "

35 wọ́n ti ń àpò ẹrù wọn, ẹnìkọ̀̀kan owó ó san fún ọjà náà lẹ́nu àpò rẹ̀! ̀wọ́n gidigidi, àwọn àti baba wọn. 36 Jakọbu baba wọn fún wọn , "ti mi pàdánù àwọn ọmọ mi. N Josẹfu mọ́, bẹ́̀ ni n Simeoni náà mọ. tún fẹ́ Benjamini lọ. Èmi ni gbogbo ohun búburú yìí ń ṣẹlẹ̀ !"

37 Nígbà náà ni Reubeni fún baba rẹ̀ , "Pa àwọn ọmọ mi méjèèjì n Benjamini padà fún , èmi ni o á lọ́wọ́, n ó mu un padà ."

38 Ṣùgbọ́n Jakọbu , "Ọmọ mi yóò a yín lọ, ̀gbọ́n rẹ̀ ti , òun nìkan ni ó nínú àwọn ọmọ ìyá rẹ̀. ohunkóhun ṣẹlẹ̀ i, ìbànújẹ́ ni yóò pa mi ni ọjọ́ ogbó mi yìí."

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também