Pular para o conteúdo
Publicidade

2 Samuẹli 15

Absalomu dìtẹ̀ Dafidi baba rẹ̀

1 Lẹ́yìn èyí náà, Absalomu pèsè kẹ̀kẹ́ àti ẹṣin fún ara rẹ̀, àti àádọ́ta ọmọkùnrin yóò máa sáré níwájú rẹ̀. 2 Absalomu dìde kùtùkùtù, ó dúró apá kan ̀ẹnu ibodè. ẹnìkan ẹjọ́ ó ń fẹ́ tọ ọba fún ìdájọ́, a é sọ́dọ̀ rẹ̀, a bi í , "Ará ìlú wo ni ìwọ?" Òun a dáhùn , "Ìránṣẹ́ rẹ ti inú ̀kan nínú ̀Israẹli ." 3 Absalomu yóò fún un , "ó, ̀ràn rẹ ṣá dára, ó tọ́, ṣùgbọ́n ẹnìkan ọba fi àṣẹ fún láti gbọ́ ̀ràn rẹ." 4 Absalomu a , "À jẹ́ fi mi ṣe onídàájọ́ ilẹ̀ yìí! olúkúlùkù ẹni ó ẹjọ́ tàbí ̀ràn kan à máa tọ̀ , èmi ìbá ṣe ìdájọ́ òtítọ́ fún un."

5 Bẹ́̀ ni ẹnìkan súnmọ́ láti tẹríba fún un, òun a nawọ́ rẹ̀, a dìímú, a fi ẹnu ó lẹ́nu. 6 Irú ìwà báyìí ni Absalomu a máa gbogbo Israẹli ó tọ́ ọba nítorí ìdájọ́, Absalomu fi fa ọkàn àwọn ènìyàn Israẹli sọ́dọ̀ rẹ̀.

7 Ó ṣe lẹ́yìn ogójì ọdún, Absalomu fún ọba , "Èmi bẹ́ ́, jẹ́ èmi ó lọ, èmi san ìlérí mi èmi ti ṣe fún Olúwa, Hebroni. 8 Nítorí ìránṣẹ́ rẹ ti jẹ́ ̀jẹ́ kan nígbà èmi ń bẹ Geṣuri Siria , Olúwa mi padà Jerusalẹmu, nítòótọ́, èmi ó sin Olúwa.’ "

9 Ọba fún un , "Máa lọ àlàáfíà." Ó dìde, ó lọ Hebroni.

10 Ṣùgbọ́n Absalomu rán àmì sáàrín gbogbo ̀Israẹli , "Nígbà ̀yin gbọ́ ìró ìpè, ̀yin , Absalomu jẹ ọba Hebroni.’ " 11 Igba ọkùnrin Absalomu ti Jerusalẹmu jáde, nínú àwọn a ti ; wọ́n lọ nínú àìmọ̀kan wọn, wọn mọ nǹkan kan. 12 Absalomu ránṣẹ́ pe Ahitofeli ará Giloni, ìgbìmọ̀ Dafidi, láti ìlú rẹ̀ , àní láti Giloni, nígbà ó ń ẹbọ. Ìdìmọ̀náà le; àwọn ènìyàn ń pọ̀ sọ́dọ̀ Absalomu.

Dafidi sálọ kúrò lórí oyè

13 Ẹnìkan fún Dafidi , "Ọkàn àwọn ọkùnrin Israẹli ṣí Absalomu."

14 Dafidi fún gbogbo àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀ ó lọ́dọ̀ rẹ̀ ni Jerusalẹmu , "dìde! jẹ́ a sálọ, nítorí ẹni yóò gbà lọ́wọ́ Absalomu; yára, a lọ kúrò, òun à yára wa , ó ibi wa, ó fi ojú idà pa ìlú run."

15 Àwọn ìránṣẹ́ ọba fún ọba , "Gẹ́gẹ́ gbogbo èyí olúwa wa ọba ń fẹ́, ó, àwa ìránṣẹ́ rẹ̀ ti murá."

16 Ọba jáde, gbogbo ilé rẹ̀ tẹ̀e. Ọba mẹ́wàá nínú àwọn obìnrin rẹ̀ sílẹ̀ láti máa ṣọ́ ilé. 17 Ọba jáde, gbogbo ènìyàn tẹ̀e, wọ́n dúró ibìkan ó jìnnà. 18 Gbogbo àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀ kọjá iwájú rẹ̀, àti gbogbo àwọn Kereti, àti gbogbo àwọn Peleti, àti gbogbo àwọn ará Gitti, ẹgbẹ̀ta (600) ọmọkùnrin ń tọ̀ ́ lẹ́yìn láti Gati , kọjá níwájú ọba.

Ìwà òótọ́ Itai ará Gitti

19 Ọba fún Ittai ará Gitti , "Èéṣe ìwọ fi ń wa lọ pẹ̀, padà, o ba ọba jókòó; nítorí àlejò ni ìwọ, ìwọ ti fi ìlú rẹ sílẹ̀. 20 Lánàá yìí ni ìwọ , èmi ó ha ìwọ máa lọ káàkiri lónìí ? Èmi ń lọ ibikíbi mo : padà, o àwọn arákùnrin rẹ padà, àánú àti òtítọ́ Olúwa pẹ̀rẹ."

21 Ittai ọba lóhùn, ó , "Olúwa ń bẹ láààyè, àti olúwa mi ọba ti ń bẹ láààyè, nítòótọ́ níbikíbi olúwa mi ọba gbé , ìbá à ṣe nínú ikú, tàbí nínú ìyè, níbẹ̀ pẹ̀ni ìránṣẹ́ rẹ yóò gbé ."

22 Dafidi fún Ittai , "Lọ o rékọjá!" Ittai ará Gitti náà rékọjá, àti gbogbo àwọn ọmọkùnrin rẹ̀, àti gbogbo àwọn ọmọ kéékèèké ó lọ́dọ̀ rẹ̀.

23 Gbogbo ìlú náà fi ohùn rara sọkún, gbogbo ènìyàn rékọjá; ọba rékọjá àfonífojì Kidironi, gbogbo àwọn ènìyàn náà rékọjá, ìhà ̀ijù.

A gbé àpótí ̀padà ìlú Jerusalẹmu

24 ó, Sadoku pẹ̀àti gbogbo àwọn ọmọ Lefi ó lọ́dọ̀ rẹ̀ ń ru àpótí ̀Ọlọ́run, wọ́n gbé àpótí ̀Ọlọ́run náà sọ̀kalẹ̀; Abiatari gòkè, títí gbogbo àwọn ènìyàn fi dẹ́kun àti máa kọjá láti ìlú .

25 Ọba fún Sadoku , "tún gbé àpótí ̀Ọlọ́run náà padà ìlú, èmi ojúrere gbà lọ́dọ̀ Olúwa, yóò tún mi padà , yóò fi àpótí ̀náà hàn àti ibùgbé rẹ̀. 26 Ṣùgbọ́n òun , Èmi inú dídùn ,ó, èmi nìyìí, jẹ́ òun ó ṣe mi gẹ́gẹ́ ó ti tọ́ ojú rẹ̀."

27 Ọba fún Sadoku àlùfáà , "Aríran ha kọ́ ni ́? Padà ìlú àlàáfíà, àti àwọn ọmọ rẹ méjèèjì pẹ̀rẹ, Ahimasi ọmọ rẹ, àti Jonatani ọmọ Abiatari. 28 ó, èmi ó dúró pẹ̀tẹ́lẹ̀ ijù náà, títí ̀rọ̀ ó fi ti ̀dọ̀ rẹ̀ láti sọ fún mi." 29 Sadoku àti Abiatari gbé àpótí ̀Ọlọ́run padà Jerusalẹmu, wọ́n gbé ibẹ̀.

Ahitofeli lọ́wọ́ ìdìtẹ̀ náà

30 Dafidi ń gòkè lọ òkè igi olifi, o ń sọkún ó ti ń gòkè lọ, ó bo orí rẹ̀, ó ń lọ láìní bàtà ẹsẹ̀, gbogbo ènìyàn o lọ́dọ̀ rẹ̀, olúkúlùkù ọkùnrin bo orí rẹ̀, wọ́n ń gòkè lọ, wọ́n ń sọkún wọ́n ti ń gòkè lọ. 31 Ẹnìkan sọ fún Dafidi , "Ahitofeli nínú àwọn aṣọ̀tẹ̀ pẹ̀Absalomu." Dafidi , "Olúwa, èmi bẹ̀ ́, sọ ìmọ̀ Ahitofeli di asán."

Huṣai padà Jerusalẹmu

32 Ó ṣe, Dafidi orí òkè, níbi ó gbé wólẹ̀ sin Ọlọ́run, ó, Huṣai ará Arki láti pàdé rẹ̀ pẹ̀aṣọ rẹ̀ yíya, àti erùpẹ̀, lórí rẹ̀. 33 Dafidi fún un , "ìwọ mi kọjá, ìwọ ó jẹ́ ìdíwọ́ fún mi. 34 ìwọ padà ìlú, o fún Absalomu , Èmi ó ṣe ìránṣẹ́ rẹ ọba, gẹ́gẹ́ èmi ti ṣe ìránṣẹ́ baba rẹ nígbà àtijọ́, bẹ́̀ ni èmi ó jẹ́ ìránṣẹ́ rẹ nísinsin yìí,ìwọ ìmọ̀ Ahitofeli jẹ́. 35 Ṣé Sadoku àti Abiatari àwọn àlùfáà níbẹ̀ pẹ̀rẹ̀? Yóò ṣe, ohunkóhun ìwọ gbọ́ láti ilé ọba , ìwọ ó sọ fún Sadoku àti Abiatari àwọn àlùfáà. 36 ó, àwọn ọmọ wọn méjèèjì níbẹ̀ pẹ̀wọn, Ahimasi ọmọ Sadoku, àti Jonatani ọmọ Abiatari; láti ọwọ́ wọn ni ̀yin ó rán ohunkóhun ̀yin gbọ́ mi."

37 Huṣai ̀rẹ́ Dafidi ìlú, Absalomu Jerusalẹmu.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também