Pular para o conteúdo
Publicidade

2 Samuẹli 1

Dafidi gbọ́ ti ikú Saulu ọba

1 Lẹ́yìn ikú Saulu, Dafidi ti ibi ó ti ṣẹ́gun àwọn ará Amaleki bọ̀, ó dúró Siklagi ọjọ́ méjì. 2 ọjọ́ kẹta, ọkùnrin kan láti ibi ibùdó Saulu, pẹ̀aṣọ rẹ̀ ó ti ya; àti erùpẹ̀ orí rẹ̀. Nígbà ó ̀dọ̀ Dafidi, ó wólẹ̀ fún un láti bu ọlá fún un.

3 Dafidi béèrè , "Ibo ni ìwọ ti ?"

"Èmi láti ibùdó àwọn ọmọ Israẹli."

4 Dafidi béèrè , "ni ó ṣẹlẹ̀?" "Sọ fún mi."

Ó , "Àwọn ọkùnrin náà láti ojú ogun. ̀pọ̀ wọn ṣubú, wọ́n . Saulu àti ọmọ rẹ̀ ọkùnrin Jonatani pẹ̀."

5 Nígbà náà, Dafidi sọ fún ̀dọ́mọkùnrin ó ìròyìn fún un , "Báwo ni o ṣe mọ̀ Saulu àti ọmọkùnrin rẹ̀ Jonatani ti ."

6 1.6-10: 1Sa 31.1-13; 1Ki 10.1-12. ̀dọ́mọkùnrin náà sọ , "Mo orí òkè Gilboa níbẹ̀ ni Saulu fi ara ọkọ̀ rẹ̀, àwọn kẹ̀kẹ́ àti ẹlẹ́ṣin ń lépa rẹ̀. 7 Nígbà ó yíká, ó , ó mi, mo , ni mo ṣe?

8 "Ó bi , Ta ni ìwọ?

"Mo dáhùn , Ará a Amaleki.

9 "Nígbà náà ó fún mi , Dúró lórí ì mi o pa ! Èmi nínú ìrora ikú, ṣùgbọ́n mo láààyè.

10 "Nígbà náà, mo dúró lórí i rẹ̀, mo pa á nítorí mo mọ̀ , lẹ́yìn ìgbà ó ti ṣubú, le è mọ́. Mo adé ó lórí rẹ̀, idẹ ó apá a rẹ̀, mo wọn síbí fún olúwa mi."

11 Nígbà náà ni, Dafidi àti gbogbo àwọn ó pẹ̀rẹ̀, di aṣọ wọn , wọ́n á ya. 12 Wọ́n ṣọ̀fọ̀, wọ́n sọkún, wọ́n gbààwẹ̀ títí di ìrọ̀lẹ́ fún Saulu àti ọmọ rẹ̀ Jonatani àti fún àwọn ọmọ-ogun Olúwa, àti fún àwọn ilé Israẹli, nítorí wọ́n ti ṣubú nípa idà.

13 Dafidi sọ fún ọkùnrin ó ìròyìn fún un , "Níbo ni ó ti ?"

O dáhùn , "Ọmọ àlejò ni mo jẹ́, ará Amaleki."

14 Dafidi béèrè lọ́wọ́ rẹ̀ , "ni ó ìwọ fi bẹ̀láti gbé ọwọ́ rẹ̀ sókè láti fi pa ẹni àmì òróró Olúwa?"

15 Nígbà náà Dafidi pe ̀kan nínú ọkùnrin, ó , "Lọ, gbé e lulẹ̀!" Nígbà náà ó gbé e lulẹ̀, ó . 16 Nítorí Dafidi fún un , "̀jẹ̀ rẹ yóò lórí ara rẹ, nítorí ẹnu ara rẹ ni o fi sọ , Mo pa ẹni àmì òróró Olúwa.’ "

17 Dafidi fi orin ̀fọ̀ yìí ṣọ̀fọ̀ lórí Saulu àti lórí Jonatani ọmọ rẹ̀, 18 Ó pàṣẹ a kọ́ àwọn ọkùnrin Juda orin arò yìí ó jẹ́ ti ọrun (a kọ ́ inú ìwé Jaṣari):

19 "Ògo rẹ, Israẹli ni a pa òkè gíga rẹ.

àwọn alágbára ṣe ń ṣubú!

20 "ṣe sọ ́ Gati,

ṣe kéde rẹ̀ òpópónà Aṣkeloni,

àwọn ọmọbìnrin Filistini à yọ̀,

àwọn ọmọbìnrin aláìkọlà ba à dunnú.

21 "̀yin òkè Gilboa,

̀yin ó ṣe ìrì tàbí òjò,

tàbí oko ó èso ọrẹ .

Nítorí ibẹ̀ ni asà alágbára ti ṣègbé,

asà Saulu, ẹni a fi òróró yàn án.

22 "Ọrun Jonatani í padà

bẹ́̀ ni idà Saulu í padà lásán,

láì kan ̀jẹ̀ àwọn a pa,

àti ẹran àwọn alágbára.

23 Saulu àti Jonatani

ọjọ́ ayé, wọ́n fẹ́ràn ara, wọn dùn,

ikú, wọn ara wọ́n.

Wọ́n yára ju idì lọ,

wọ́n lágbára ju kìnnìún lọ.

24 "̀yin ọmọbìnrin Israẹli,

sọkún lórí Saulu,

ẹni ó fi aṣọ ̀gbọ̀ dáradára wọ̀ yín,

ẹni ó fi wúrà ara aṣọ yín.

25 "ó alágbára ti ṣubú ojú ogun!

Jonatani, ìwọ a pa òkè gíga.

26 Ọkàn mi gbọgbẹ́ fún Jonatani arákùnrin mi;

ìwọ ṣọ̀wọ́n fún mi.

Ìfẹ́ rẹ mi jẹ́ ìyanu,

ó jẹ́ ìyanu ju ti obìnrin lọ.

27 "ó alágbára ti ṣubú!

Ohun ìjà ti ṣègbé!"

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também