Pular para o conteúdo
Publicidade

2 Samuẹli 11

Dafidi àti Batṣeba

1 11.1: 1Ki 20.1. Lẹ́yìn ìgbà ọdún yípo, àkókò ìgbà àwọn ọba máa ń jáde ogun, Dafidi rán Joabu, àti àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀ pẹ̀rẹ̀, àti gbogbo Israẹli; wọ́n pa àwọn ọmọ Ammoni, wọ́n ti Rabba. Dafidi jókòó Jerusalẹmu.

2 Ó ṣe, ìgbà àṣálẹ́ kan, Dafidi dìde ibùsùn rẹ̀, ó ń rìn lórí òrùlé ilé ọba, láti orí òrùlé náà ni ó obìnrin kan ó ń wẹ̀ ara rẹ̀; obìnrin náà ṣe arẹwà lójú láti . 3 Dafidi ránṣẹ́ ó béèrè obìnrin náà. Ẹnìkan , "Èyí ha kọ́ ni Batṣeba, ọmọbìnrin Eliamu, aya Uriah ará Hiti." 4 Dafidi rán àwọn ìránṣẹ́, ó un; ó wọ inú ilé tọ̀ ́ lọ, ó a dàpọ̀, nígbà ó wẹ ara rẹ̀ mọ́ tán, ó padà lọ ilé rẹ̀. 5 Obìnrin náà lóyún, ó ránṣẹ́ ó sọ fún Dafidi, ó , "Èmi ti lóyún."

Dafidi tan Uriah sílé

6 Dafidi ránṣẹ́ Joabu, , "Rán Uriah ará Hiti mi." Joabu rán Uriah Dafidi. 7 Nígbà Uriah ̀dọ̀ rẹ̀, Dafidi bi í léèrè báwo ni Joabu ti ṣe àti àlàáfíà àwọn ènìyàn náà, àti ogun náà ti ń ṣe. 8 Dafidi fún Uriah , "Sọ̀kalẹ̀ lọ ilé rẹ, o wẹ ẹsẹ̀ rẹ." Uriah jáde kúrò ilé ọba, oúnjẹ láti ̀dọ̀ ọba tọ̀ ́ lẹ́yìn. 9 Ṣùgbọ́n Uriah sun ẹnu-ọ̀ilé ọba lọ́dọ̀ gbogbo ìránṣẹ́ olúwa rẹ̀, sọ̀kalẹ̀ lọ ilé rẹ̀.

10 Nígbà wọ́n sọ fún Dafidi , "Uriah sọ̀kalẹ̀ lọ ilé rẹ̀," Dafidi fún Uriah , "Ṣe ̀àjò ni ìwọ ti ? Èéha ti ṣe ìwọ fi sọ̀kalẹ̀ lọ ilé rẹ."

11 Uriah fún Dafidi , "Àpótí ̀, àti Israẹli, àti Juda jókòó nínú àgọ́; àti Joabu olúwa mi, àti àwọn ìránṣẹ́ olúwa mi ibùdó pápá, èmi ó ha lọ ilé mi, láti jẹ àti láti mu, àti láti obìnrin mi sùn? ìwọ láààyè, àti ̀rẹ́ si ti ń bẹ láààyè, èmi yóò ṣe nǹkan yìí."

12 Dafidi fún Uriah , "dúró níhìn-ín lónìí, lọ́la èmi ó jẹ́ ìwọ ó lọ." Uriah dúró Jerusalẹmu ọjọ́ náà, àti ọjọ́ kejì. 13 Dafidi é, ó jẹ, ó nítorí rẹ̀; ó mu ọtí pa á; òun jáde alẹ́ lọ ibùsùn rẹ̀ lọ́dọ̀ àwọn ìránṣẹ́ olúwa rẹ̀, sọ̀kalẹ̀ lọ ilé rẹ̀.

Dafidi pàṣẹ wọn ó pa Uriah ogun

14 Ó ṣe òwúrọ̀, Dafidi kọ̀Joabu, ó fi rán Uriah. 15 Ó kọ sínú ìwé , "Fi Uriah síwájú ibi ogun gbé le, fàsẹ́yìn, wọn kọlù ú, ó ."

16 Ó ṣe nígbà Joabu ṣe àkíyèsí ìlú náà, ó yan Uriah ibi kàn ibi òun mọ̀ àwọn alágbára ọkùnrin ń bẹ níbẹ̀. 17 Àwọn ọkùnrin ìlú náà jáde , wọ́n Joabu , díẹ̀ ṣubú nínú àwọn ènìyàn náà nínú àwọn ìránṣẹ́ Dafidi, Uriah ará Hiti pẹ̀.

18 Joabu ránṣẹ́ ó ro gbogbo nǹkan ogun náà fún Dafidi. 19 Ó pàṣẹ fún ìránṣẹ́ náà , "Nígbà ìwọ parí àti máa ro gbogbo nǹkan ogun náà fún ọba. 20 ó ṣe , ìbínú ọba ru, ti òun fún , Èéṣe ̀yin fi súnmọ́ ìlú náà láti wọn , ̀yin mọ̀ wọn ó tafà láti orí odi . 21 Ta ni ó pa Abimeleki ọmọ Jerubu-Beṣeti? í ṣe obìnrin ni ó òkúta-ọlọ ú láti orí odi , ó Tebesi? Èéha ti ̀yin fi súnmọ́ odi náà? Ìwọ yóò fún un , Uriah ìránṣẹ́ rẹ ará Hiti pẹ̀.’ "

22 Ìránṣẹ́ náà lọ, ó , ó jẹ́ gbogbo iṣẹ́ Joabu rán an fún Dafidi. 23 Ìránṣẹ́ náà fún Dafidi , "Nítòótọ́ àwọn ọkùnrin náà lágbára lọ, wọ́n jáde tọ̀ pápá, àwa tẹ̀wọn títí wọ́n fi ̀yìn odi. 24 Àwọn tafàtafà ta ìránṣẹ́ rẹ láti orí odi , díẹ̀ nínú àwọn ìránṣẹ́ ọba , ìránṣẹ́ rẹ̀ Uriah ará Hiti pẹ̀."

25 Dafidi fún ìránṣẹ́ náà , "Báyìí ni ìwọ yóò fún Joabu , ṣe jẹ́ nǹkan yìí burú ojú rẹ, nítorí idà a máa pa lọ́tùn ún lósì, ìjà rẹ le ìlú náà, o í ṣubú.ìwọ un lọ́kàn le."

Dafidi fẹ́ Batṣeba ìyàwó

26 Nígbà aya Uriah gbọ́ Uriah ọkọ rẹ̀ , ó ṣọ̀fọ̀ nítorí ọkọ rẹ̀. 27 Nígbà ìṣọ̀fọ̀ náà kọjá tan, Dafidi ránṣẹ́, o un ilé rẹ̀, ó di aya rẹ̀, ó ọmọkùnrin kan fún un, ṣùgbọ́n nǹkan náà Dafidi ṣe burú níwájú Olúwa.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também