Pular para o conteúdo
Publicidade

2 Samuẹli 10

Dafidi ṣẹ́gun Ammoni

1 10.1-19: 1Ki 19.1-19. Ó ṣe lẹ́yìn èyí, ọba àwọn ará Ammoni , Hanuni ọmọ rẹ̀ jẹ ọba ipò rẹ̀. 2 Dafidi , "Èmi yóò ṣe oore fún Hanuni ọmọ Nahaṣi gẹ́gẹ́ baba rẹ̀ ti ṣe oore fún mi." Dafidi ránṣẹ́ láti Hanuni nínú láti ọwọ́ àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀ , nítorí ti baba rẹ̀.

Àwọn ìránṣẹ́ Dafidi ilé àwọn ọmọ Ammoni. 3 Àwọn olórí àwọn ọmọ Ammoni fún Hanuni olúwa wọn , "Ǹjẹ́ o Dafidi ń bu ọlá fún baba rẹ nígbà ó rán ènìyàn láti kẹ́dùn? ha ṣe Dafidi rán àwọn ìránṣẹ́ láti wo ìlú àti láti yọ́ àti láti gbà ́." 4 Hanuni àwọn ìránṣẹ́ Dafidi ó apá kan irùngbọ̀n wọn, ó ààbọ̀ kúrò agbádá wọn, títí ó fi ìdí wọn, ó rán wọn lọ.

5 Wọ́n sọ fún Dafidi, ó ránṣẹ́ lọ pàdé wọn, nítorí ojú ti àwọn ọkùnrin náà púpọ̀: ọba , "dúró Jeriko títí irùngbọ̀n yín yóò fi , nígbà náà ni máa bọ̀."

Àwọn ogun Siria àti Ammoni níwájú Israẹli

6 Àwọn ará Ammoni ri , wọ́n di ẹni ìríra níwájú Dafidi, àwọn ọmọ Ammoni ránṣẹ́, wọ́n fi owó bẹ́ ogún àwọn ará Siria ti Beti-Rehobu; àti Siria-Soba, ogún ẹgbẹ̀rún (20,000) ẹlẹ́ṣẹ̀ àti ti ọba Maaka, ẹgbẹ̀rún (1,000) ọkùnrin àti ti Tobu ẹgbàá mẹ́(12,000) ọkùnrin lọ́wẹ̀.

7 Dafidi gbọ́, ó rán Joabu, àti gbogbo ogún àwọn ọkùnrin alágbára. 8 Àwọn ọmọ Ammoni jáde , wọ́n tẹ́ ogun ẹnu odi; ará Siria-Soba, àti ti Rehobu, àti Tobu, àti Maaka, wọ́n tẹ ogun ni pápá fún ara wọn.

9 Nígbà Joabu i ogun náà dojúkọ òun níwájú àti lẹ́yìn, ó yàn nínú gbogbo àwọn akíkanjú ọkùnrin Israẹli, ó tẹ́ ogun kọjú àwọn ará Siria. 10 Ó fi àwọn ènìyàn ó Abiṣai àbúrò rẹ̀ lọ́wọ́, ó tẹ ogun kọjú àwọn ọmọ Ammoni. 11 Ó , "agbára àwọn ará Siria pọ̀ ju èmi lọ, ìwọ yóò ràn lọ́wọ́, ṣùgbọ́n ọwọ́ àwọn ọmọ Ammoni pọ̀́ lọ, èmi ó ràn ́ lọ́wọ́. 12 ọkàn , jẹ́ a ṣe onígboyà nítorí àwọn ènìyàn wa, àti nítorí àwọn ìlú Ọlọ́run wa; Olúwa yóò ṣe èyí ó dára lójú rẹ̀."

13 Joabu àti àwọn ènìyàn ń bẹ lọ́dọ̀ rẹ̀ àwọn ará Siria pàdé ìjà, wọ́n níwájú rẹ̀. 14 Nígbà àwọn ọmọ Ammoni i àwọn ará Siria , àwọn pẹ̀níwájú Abiṣai, wọ́n wọ inú ìlú lọ. Joabu padà kúrò lẹ́yìn àwọn ọmọ Ammoni, ó Jerusalẹmu.

Ìṣẹ́gun lórí ogun Ammoni àti Siria Helami

15 Nígbà àwọn ará Siria i àwọn ṣubú níwájú Israẹli, wọ́n ara wọn jọ 16 Hadadeseri ránṣẹ́, ó àwọn Siria ó òkè odò Eufurate jáde , wọ́n Helami; Sobaki olórí ogun Hadadeseri ṣe olórí wọn.

17 Nígbà a sọ fún Dafidi, ó gbogbo Israẹli jọ, wọ́n kọjá Jordani, wọ́n Helami, àwọn ará Siria tẹ́ ogun kọjú Dafidi, wọ́n a . 18 Àwọn ará Siria níwájú Israẹli, Dafidi pa nínú àwọn ará Siria ̀́dẹ́gbẹ̀rin (700) àwọn oníkẹ̀kẹ́, àti ̀kẹ́ méjì (40,000) ẹlẹ́ṣin, wọ́n kọlu Sobaki olórí ogun wọn, ó níbẹ̀. 19 Nígbà gbogbo àwọn ọba ó lábẹ́ Hadadeseri i wọ́n di bíbì ṣubú níwájú Israẹli, wọ́n Israẹli làjà, wọ́n ń sìn wọ́n.

Àwọn ará Siria bẹ̀láti máa ran àwọn ọmọ Ammoni lọ́wọ́ mọ́.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também