Pular para o conteúdo
Publicidade

2 Samuẹli 18

Wọ́n pàdé ogun igbó Efraimu

1 Dafidi ka àwọn ènìyàn ń bẹ lọ́dọ̀ rẹ̀, ó wọn jẹ balógun ẹgbẹẹgbẹ̀rún, àti balógun ̀rọ̀̀rún lórí wọn. 2 Dafidi fi ìdámẹ́ta àwọn ènìyàn náà Joabu lọ́wọ́, ó rán wọn lọ, àti ìdámẹ́ta Abiṣai ọmọ Seruiah àbúrò Joabu lọ́wọ́ àti ìdámẹ́ta Ittai ará Gitti lọ́wọ́, ọba fún àwọn ènìyàn náà , "Nítòótọ́ èmi tìkára mi yóò yín lọ pẹ̀."

3 Àwọn ènìyàn náà , "Ìwọ yóò wa lọ, nítorí àwa , wọn yóò náání wa, tàbí ó tilẹ̀ ṣe ìdajì wa , wọn yóò náání wa, nítorí ìwọ nìkan ẹgbẹ̀rún mẹ́wàá (10,000) wa. Nítorí náà, ó dára ìwọ máa ràn lọ́wọ́ láti ìlú ."

4 Ọba fún wọn , "Èyí ó tọ́ lójú yin ni èmi ó ṣe."

Ọba dúró apá kan ẹnu odi, gbogbo àwọn ènìyàn náà jáde ̀rọ̀̀rún àti ẹgbẹẹgbẹ̀rún. 5 Ọba pàṣẹ fún Joabu àti Abiṣai àti Ittai , "tọ́̀dọ́mọkùnrin náà Absalomu fún mi." Gbogbo àwọn ènìyàn náà gbọ́ nígbà ọba pàṣẹ fún gbogbo àwọn balógun nítorí Absalomu.

6 Àwọn ènìyàn náà jáde láti pàdé Israẹli pápá; igbó Efraimu ni wọ́n gbé pàdé ìjà náà. 7 Níbẹ̀ ni a gbé pa àwọn ènìyàn Israẹli níwájú àwọn ìránṣẹ́ Dafidi, ̀pọ̀lọpọ̀ ènìyàn ni ó ṣubú lọ́jọ́ náà, àní ogún ẹgbẹ̀rún (20,000) ènìyàn. 8 Ogun náà fọ́n káàkiri lórí gbogbo ilẹ̀ náà, igbó náà pa ̀pọ̀ ènìyàn ju èyí idà pa lọ lọ́jọ́ náà.

Joabu kọlu Absalomu

9 Absalomu pàdé àwọn ìránṣẹ́ Dafidi. Absalomu gun orí ìbáaka kan, ìbáaka náà gba abẹ́ ̀ka ńlá igi óákù kan ó tóbi lọ, orí rẹ̀ kọ́ igi óákù náà òun rọ̀ sókè agbede-méjì ̀run àti ilẹ̀; ìbáaka náà ó lábẹ́ rẹ̀ lọ kúrò.

10 Ọkùnrin kan i, ó fún Joabu , "ó, èmi Absalomu so rọ̀ láàrín igi óákù kan."

11 Joabu fún ọkùnrin náà ó sọ fún un , "ó, ìwọ i, èéha ti ṣe ìwọ fi ú bolẹ̀ níbẹ̀? Èmi ìbá fún ṣékélì fàdákà mẹ́wàá, àti àmùrè kan."

12 Ọkùnrin náà fún Joabu , "èmi tilẹ̀ gba ẹgbẹ̀rún (1,000) ṣékélì fàdákà ọwọ́ , èmi yóò fi ọwọ́ mi kan ọmọ ọba, nítorí àwa gbọ́ nígbà ọba kìlọ̀ fún ìwọ àti Abiṣai, àti Ittai, , kíyèsi i, ẹnikẹ́ni ṣe fi ọwọ́ kan ̀dọ́mọkùnrin náà Absalomu.13 ó ṣe bẹ́̀ èmi ìbá ṣe ara mi, nítorí ̀ràn kan ó pamọ́ fún ọba, ìwọ tìkára rẹ̀ ìbá kọjú ìjà mi pẹ̀."

14 Joabu , "Èmi yóò dúró bẹ́̀ níwájú rẹ." Ó ̀kọ̀ mẹ́ta lọ́wọ́ rẹ̀, ó fi wọ́n gún Absalomu ọkàn, nígbà ó láààyè agbede-méjì igi óákù náà. 15 Àwọn ̀dọ́mọdékùnrin mẹ́wàá ó máa ń ru ìhámọ́ra Joabu Absalomu , wọ́n kọlù ú, wọ́n pa á.

16 Joabu fun ìpè, àwọn ènìyàn náà yípadà láti máa lépa Israẹli, nítorí Joabu ti pe àwọn ènìyàn náà padà. 17 Wọ́n gbé Absalomu, wọ́n sọ ́ sínú ihò ńlá kan igbó náà, wọ́n òkúta púpọ̀ jọ i lórí, gbogbo Israẹli , olúkúlùkù inú àgọ́ rẹ̀.

18 Absalomu ìgbà ayé rẹ̀, mọ ̀wọ́n kan fún ara rẹ̀, ń bẹ àfonífojì Ọba: nítorí ó , "Èmi ọmọkùnrin yóò pa orúkọ mi mọ́ ìrántí," òun pe ̀wọ́n náà nípa orúkọ rẹ̀, a ń é títí di òní, ̀wọ́n Absalomu.

Dafidi ṣọ̀fọ̀

19 Ahimasi ọmọ Sadoku , "Jẹ́ èmi ó súré nísinsin yìí, èmi ìròyìn tọ ọba lọ, Olúwa ti gbẹ̀san rẹ̀ lára àwọn ̀rẹ̀."

20 Joabu fún un , "Ìwọ yóò ìròyìn lọ lónìí, ṣùgbọ́n ìwọ ó lọ ọjọ́ mìíràn, ṣùgbọ́n lónìí yìí ìwọ yóò ìròyìn kan lọ, nítorí ọmọ ọba ṣe aláìsí."

21 Joabu fún Kuṣi , "Lọ, ìwọ ro ohun ìwọ fún ọba." Kuṣi wólẹ̀ fún Joabu ó sáré.

22 Ahimasi ọmọ Sadoku tún fún Joabu , "Jọ̀wọ́, ó ti ó , èmi ó sáré tọ Kuṣi lẹ́yìn."

Joabu bi í , "Nítorí kín ni ìwọ ó ṣe sáré, ọmọ mi, ìwọ ri ìròyìn rere kan ìwọ ó lọ."

23 Ó , "ó ti ó , èmi ó sáré."

Ó fún un , "Sáré!" Ahimasi sáré ̀pẹ̀tẹ́lẹ̀, ó sáré kọjá Kuṣi.

24 Dafidi jókòó lẹ́nu odi láàrín ìlẹ̀kùn méjì, alóre gòkè òrùlé bodè lórí odi, ó gbé ojú rẹ̀ sókè, ó , ó, ọkùnrin kan ń sáré òun nìkan. 25 Alóre náà kígbe, ó fún ọba.

Ọba , "ó ṣe òun nìkan ni, ìròyìn rere ń bẹ lẹ́nu rẹ̀." Òun ń súnmọ́ tòsí.

26 Alóre náà ọkùnrin mìíràn ń sáré, alóre kọ ẹni ń ṣọ́ bodè, ó pe, "ó, ọkùnrin kan ń sáré òun nìkan."

Ọba , "Èyí náà pẹ̀ń ìròyìn rere ."

27 Alóre náà , "Èmi wo ìsáré ẹni ó níwájú ó dàbí ìsáré Ahimasi ọmọ Sadoku."

Ọba , "Ènìyàn re ni, ó ń ìyìnrere !"

28 Ahimasi , ó fún ọba , "Àlàáfíà!" Ó wólẹ̀ fún ọba, ó dojúbolẹ̀ ó , "Alábùkún fún ni Olúwa Ọlọ́run rẹ, ẹni ó fi àwọn ọkùnrin ó gbé ọwọ́ wọn sókè olúwa mi ọba lọ́wọ́."

29 Ọba béèrè , "Àlàáfíà ha fún Absalomu, ọmọdékùnrin náà ?"

Ahimasi dáhùn , "Nígbà Joabu rán ìránṣẹ́ ọba, àti èmi ìránṣẹ́ rẹ̀, mo ̀pọ̀ ènìyàn, ṣùgbọ́n èmi mọ ìdí rẹ̀."

30 Ọba fún un , "Yípadà o dúró níhìn-ín." Òun yípadà, ó dúró jẹ́́.

31 ó, Kuṣi , "Ìyìnrere fún olúwa mi ọba, nítorí Olúwa ti gbẹ̀san rẹ lónìí lára gbogbo àwọn ó dìde ."

32 Ọba bi Kuṣi , "Àlàáfíà kọ́ Absalomu ̀dọ́mọdékùnrin náà ?"

Kuṣi dáhùn pe, "àwọn ̀olúwa mi ọba, àti gbogbo àwọn ó dìde ibi, ̀dọ́mọdékùnrin náà."

33 Ọba kẹ́dùn púpọ̀ ó gòkè lọ, yàrá ó lórí òkè ibodè, ó sọkún; báyìí ni ó ń ó ti ń lọ, "Ọmọ mi Absalomu! Ọmọ mi, ọmọ Absalomu! Á à! Ìbá ṣe èmi ni ó ipò rẹ̀! Absalomu ọmọ mi, ọmọ mi!"

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também