Pular para o conteúdo
Publicidade

2 Samuẹli 19

Joabu Dafidi gidigidi

1 A fún Joabu pe, "ó, ọba ń sọkún, ó ń gbààwẹ̀ fún Absalomu." 2 Ìṣẹ́gun ọjọ́ náà di àwẹ̀ fún gbogbo àwọn ènìyàn náà, nítorí àwọn ènìyàn náà gbọ́ ọjọ́ náà inú ọba ti bàjẹ́ nítorí ọmọ rẹ̀. 3 Àwọn ènìyàn náà yọ́ lọ ìlú ọjọ́ náà gẹ́gẹ́ àwọn ènìyàn a dójútì ṣe máa ń yọ́ lọ nígbà wọ́n lójú ìjà. 4 Ọba bo ojú rẹ̀, ọba kígbe ohùn rara , "Á à! Ọmọ mi Absalomu! Absalomu ọmọ mi, ọmọ mi!"

5 Joabu wọ inú ilé tọ ọba lọ, ó , "Ìwọ dójúti gbogbo àwọn ìránṣẹ́ rẹ lónìí, àwọn ó gba ̀rẹ̀ lónìí, àti ̀àwọn ọmọkùnrin rẹ̀, àti ti àwọn ọmọbìnrin rẹ̀, àti àwọn aya rẹ̀, àti ̀àwọn obìnrin rẹ. 6 Nítorí ìwọ fẹ́ àwọn ̀rẹ, ìwọ kórìíra àwọn ̀rẹ́ rẹ. Nítorí ìwọ lónìí , Ìwọ náání àwọn ọmọ ọba tàbí àwọn ìránṣẹ́; èmi lónìí , ìbá ṣe Absalomu láààyè, gbogbo wa lónìí, ǹjẹ́ ìbá dùn mọ́ gidigidi. 7 dìde nísinsin yìí, lọ, o sọ̀rọ̀ ìtùnú fún àwọn ìránṣẹ́ rẹ, nítorí èmi fi Olúwa búra, ìwọ lọ, ẹnìkan yóò dúró ni alẹ́ yìí, èyí ni yóò burú fún ju gbogbo ibi ojú rẹ ti ń láti ìgbà èwe rẹ títí ó fi di ìsinsin yìí."

8 Ọba dìde, ó jókòó ẹnu-ọ̀, wọ́n fún gbogbo àwọn ènìyàn náà , "ó, ọba jókòó ẹnu-ọ̀." Gbogbo ènìyàn iwájú ọba.

Nítorí , Israẹli ti , olúkúlùkù àgọ́ rẹ̀.

Àwọn àgbà Dafidi ọba padà

9 Gbogbo àwọn ènìyàn náà ń ara wọn nínú gbogbo ̀Israẹli, , "Ọba ti gbà lọ́wọ́ àwọn ̀wa, ó ti gbà kúrò lọ́wọ́ àwọn Filistini; òun kúrò ìlú nítorí Absalomu. 10 Absalomu, àwa fi jẹ ọba lórí wa ogun, ǹjẹ́ èéṣe ̀yin fi dákẹ́ ̀yin sọ̀rọ̀ kan láti ọba padà ?"

11 Dafidi ọba ránṣẹ́ Sadoku, àti Abiatari àwọn àlùfáà , "Sọ fún àwọn àgbàgbà Juda, , Èéṣe ̀yin fi kẹ́yìn láti ọba padà ilé rẹ̀? ̀rọ̀ gbogbo Israẹli ti ̀dọ̀ ọba àní ilé rẹ̀. 12 ̀yin ni ara mi, ̀yin ni egungun mi, àti ẹran-ara mi: èéṣì ti ṣe ̀yin fi kẹ́yìn láti ọba padà .13 ̀yin fún Amasa , Egungun àti ẹran-ara mi kọ́ ni ìwọ jẹ́ ? Ọlọ́run ó ṣe bẹ́̀ mi àti bẹ́̀ lọ pẹ̀, ìwọ ba ṣe olórí ogun níwájú mi títí, ipò Joabu.’ "

14 Òun gbogbo àwọn ọkùnrin Juda lọ́kàn padà àní ọkàn ènìyàn kan; wọ́n ránṣẹ́ ọba, , "Ìwọ padà àti gbogbo àwọn ìránṣẹ́ rẹ." 15 Ọba padà, o odò Jordani.

Juda Gilgali láti lọ pàdé ọba, àti láti ọba kọjá odò Jordani.

Ọba dáríjì Ṣimei

16 Ṣimei ọmọ Gera, ará Benjamini ti Bahurimu, ó yára ó àwọn ọkùnrin Juda sọ̀kalẹ̀ láti pàdé Dafidi ọba. 17 Ẹgbẹ̀rún ọmọkùnrin lọ́dọ̀ rẹ̀ nínú àwọn ọmọkùnrin Benjamini, Ṣiba ìránṣẹ́ ilé Saulu, àti àwọn ọmọkùnrin rẹ̀ mẹ́̀́dógún àti ogún ìránṣẹ́ pẹ̀rẹ̀; wọ́n gòkè odò Jordani ṣáájú ọba. 18 Ọkọ̀ èrò kan ti rékọjá láti àwọn ènìyàn ilé ọba òkè, àti láti ṣe èyí ó tọ́ lójú rẹ̀.

Ṣimei ọmọ Gera wólẹ̀. Ó dojúbolẹ̀ níwájú ọba, ó gòkè odò Jordani. 19 Ó fún ọba , "olúwa mi ó ṣe ka ̀ṣẹ̀ mi lọ́rùn, ṣe rántí àfojúdi ìránṣẹ́ rẹ̀ ṣe ni ọjọ́ olúwa mi ọba jáde Jerusalẹmu, ọba fi inú. 20 Nítorí ìránṣẹ́ rẹ mọ̀ èmi ti ṣẹ̀; ó, mo lónìí yìí, ẹni àkọ́kọ́ gbogbo ìdílé Josẹfu yóò sọ̀kalẹ̀ pàdé olúwa mi ọba."

21 Ṣùgbọ́n Abiṣai ọmọ Seruiah dáhùn ó , "ha tọ́ a pa Ṣimei nítorí èyí? Nítorí òun ti ẹni àmì òróró Olúwa."

22 Dafidi , "ni èmi ṣe pẹ̀yín, ̀yin ọmọ Seruiah dàbí ̀fún mi lónìí? A ha pa ènìyàn kan lónìí Israẹli? Tàbí èmi ha mọ̀ lónìí èmi ni ọba Israẹli." 23 Ọba fún Ṣimei , "Ìwọ yóò !" Ọba búra fún un.

Mefiboṣeti ṣe àlàyé fún Dafidi

24 Mefiboṣeti ọmọ Saulu sọ̀kalẹ̀ láti pàdé ọba, wẹ ẹsẹ̀ rẹ̀, tọ́ irùngbọ̀n rẹ̀, bẹ́̀ ni fọ aṣọ rẹ̀ láti ọjọ́ ọba ti jáde títí ó fi di ọjọ́ ó fi padà àlàáfíà. 25 Nígbà òun Jerusalẹmu láti pàdé ọba, ọba fún un , "Èéṣe ìwọ fi mi lọ, Mefiboṣeti?"

26 Òun dáhùn , "Olúwa mi, ọba, ìránṣẹ́ mi ni ó tàn , nítorí ìránṣẹ́ rẹ fún un , Di kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ gàárì fún mi èmi ó gùn ún, èmi ó tọ ọba lọ.Nítorí ìránṣẹ́ rẹ yarọ. 27 Ó sọ̀rọ̀ ìbàjẹ́ ìránṣẹ́ rẹ, fún olúwa mi ọba, ṣùgbọ́n angẹli Ọlọ́run ni olúwa mi ọba , nítorí náà ṣe èyí ó dára lójú rẹ. 28 Nítorí gbogbo ilé baba mi òkú ènìyàn ni wọ́n à níwájú olúwa mi ọba, ìwọ fi ipò fún ìránṣẹ́ rẹ láàrín àwọn ó ń jẹun ibi oúnjẹ. Nítorí náà àre kín ni èmi èmi yóò fi máa pe ọba síbẹ̀."

29 Ọba fún un , "Èéṣe ìwọ fi ń sọ ̀ràn ara rẹ fún mi èmi à ti , ìwọ àti Ṣiba pín ilẹ̀ náà."

30 Mefiboṣeti fún ọba , "Jẹ́ ó gbogbo rẹ̀, olúwa mi ọba à ti padà bọ̀ ilé rẹ̀ ni àlàáfíà."

Dafidi súre fún Barsillai

31 Barsillai ará Gileadi sọ̀kalẹ̀ láti Rogelimu , ó ọba gòkè odò Jordani, láti ṣe ìkẹ́ rẹ̀ ìkọjá odò Jordani. 32 Barsillai jẹ́ arúgbó ọkùnrin gidigidi, ẹni ogbó ọgọ́rin ọdún ni, ó pèsè ohun jíjẹ fún ọba nígbà ó ti Mahanaimu; nítorí ọkùnrin ọlọ́ni òun ń ṣe. 33 Ọba fún Barsillai , "Ìwọ mi gòkè odò, èmi ó máa pèsè fún Jerusalẹmu."

34 Barsillai fún ọba , "Ọjọ́ mélòó ni ọdún ̀mi , èmi ó fi ọba gòkè lọ Jerusalẹmu. 35 Ẹni ogbó ọgọ́rin ọdún à ni èmi lónìí, ǹjẹ́ èmi mọ ìyàtọ̀ nínú rere àti búburú? Ǹjẹ́ ìránṣẹ́ rẹ le mọ adùn ohun òun ń jẹ tàbí ohun ti òun ń mu ? Èmi tún mọ adùn ohùn àwọn ọkùnrin ń kọrin àti àwọn obìnrin ń kọrin , ǹjẹ́ nítorí kín ni ìránṣẹ́ rẹ yóò ṣe jẹ́ ìyọnu síbẹ̀ fún olúwa mi ọba. 36 Ìránṣẹ́ rẹ yóò sin ọba lọ díẹ̀ gòkè odò Jordani; èéṣì ṣe ọba yóò fi san ̀san yìí fún mi. 37 Èmi bẹ̀ ́, jẹ́ ìránṣẹ́ rẹ padà, èmi ó ìlú mi, a ó sin ibojì baba àti ìyá mi. wo Kimhamu ìránṣẹ́ rẹ, yóò olúwa mi ọba gòkè; ìwọ ó ṣe ohun ó tọ́ lójú rẹ fún un."

38 Ọba dáhùn , "Kimhamu yóò mi gòkè, èmi ó ṣe èyí ó tọ́ lójú rẹ̀ fún un; ohunkóhun ìwọ béèrè lọ́wọ́ mi, èmi ó ṣe é fún ."

39 Gbogbo àwọn ènìyàn gòkè odò Jordani ọba gòkè; ọba fi ẹnu ko Barsillai lẹ́nu, ó súre fún un; òun padà ilé rẹ̀.

40 Ọba ń lọ́ Gilgali, Kimhamu ń a lọ, gbogbo àwọn ènìyàn Juda ń ṣe ìkẹ́ ọba, àti ààbọ̀ àwọn ènìyàn Israẹli.

Israẹli ń jowú

41 ó, gbogbo àwọn ọkùnrin Israẹli tọ ọba , wọ́n fún ọba , "Èéṣe àwọn arákùnrin wa àwọn ọkùnrin Juda fi kúrò, wọ́n fi ọba àti àwọn ará ilé rẹ̀ gòkè odò Jordani, àti gbogbo àwọn ènìyàn Dafidi pẹ̀rẹ?"

42 Gbogbo ọkùnrin Juda àwọn ọkùnrin Israẹli lóhùn , "Nítorí ọba wa tan ni; èéṣe ̀yin fi bínú nítorí ̀ràn yìí? Àwa jẹ nínú oúnjẹ ọba rárá ? Tàbí ó fi ̀bùn kan fún wa ?"

43 Àwọn ọkùnrin Israẹli náà àwọn ọkùnrin Juda lóhùn , "Àwa ipá mẹ́wàá nínú ọba, àwa nínú Dafidi yín lọ, èéṣì ṣe ̀yin fi , ìmọ̀ wa fi ṣáájú láti ọba wa padà?"

̀rọ̀ àwọn ọkùnrin Juda le ju ̀rọ̀ àwọn ọkùnrin Israẹli.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também