Pular para o conteúdo
Publicidade

2 Samuẹli 24

Kíka àwọn ènìyàn Israẹli

1 24.1-25: 1Ki 21.1-27. Ìbínú Olúwa ru Israẹli, ó ti Dafidi wọn, , "Lọ ka iye Israẹli àti Juda!"

2 Ọba fún Joabu olórí ogun, ń bẹ lọ́dọ̀ rẹ̀ , "Lọ ìsinsin yìí gbogbo ̀Israẹli láti Dani títí Beerṣeba, ka iye àwọn ènìyàn, èmi mọ iye àwọn ènìyàn náà!"

3 Joabu fún ọba , "Olúwa Ọlọ́run rẹ fi kún iye àwọn ènìyàn náà, iyekíye ó wọn jẹ́, ̀rọ̀̀rún, ojú olúwa mi ọba yóò i, ṣùgbọ́n èétiṣe olúwa mi ọba fi fẹ́ nǹkan yìí?"

4 Ṣùgbọ́n ̀rọ̀ ọba borí ti Joabu, àti ti àwọn olórí ogun. Joabu àti àwọn olórí ogun jáde lọ kúrò níwájú ọba, láti lọ ka àwọn ènìyàn Israẹli.

5 Wọ́n kọjá odò Jordani, wọ́n pàgọ́ Aroeri, ìhà apá ̀tún ìlú ó láàrín àfonífojì Gadi, àti ìhà Jaseri. 6 Wọ́n Gileadi, àti ilé Tatimi Hodṣi; wọ́n Dani Jaani àti yíkákiri Sidoni. 7 Wọ́n ìlú olódi Tire, àti gbogbo ìlú àwọn Hifi, àti ti àwọn ará Kenaani, wọ́n jáde lọ síhà gúúsù ti Juda, àní Beerṣeba.

8 Wọ́n la gbogbo ilẹ̀ náà , wọ́n Jerusalẹmu òpin oṣù kẹsànán àti ogúnjọ́.

9 Joabu fi iye àwọn ènìyàn náà jásí ọba lọ́wọ́. Ó jẹ́ ogójì ̀kẹ́ (800,000) ọkùnrin alágbára Israẹli, àwọn onídà, àwọn ọkùnrin Juda jẹ́ ̀kẹ́ mẹ́̀́dọ́gbọ̀n (500,000) ènìyàn.

Dafidi yan ìbáwí Olúwa

10 Àyà Dafidi gbọgbẹ́ lẹ́yìn ìgbà ó ka àwọn ènìyàn náà tán. Dafidi fún Olúwa , "Èmi ṣẹ̀ gidigidi èyí èmi ṣe, ṣùgbọ́n, èmi bẹ̀ , Olúwa, fi ̀ṣẹ̀ ìránṣẹ́ rẹ , nítorí èmi hùwà aṣiwèrè gidigidi!"

11 Dafidi dìde òwúrọ̀, ̀rọ̀ Olúwa tọ Gadi wòlíì , aríran Dafidi , 12 "Lọ o fún Dafidi , Báyìí ni Olúwa , èmi fi nǹkan mẹ́ta lọ̀ ́; yan ̀kan nínú wọn, èmi ó ṣe é .’ "

13 Gadi tọ Dafidi , ó bi í léèrè , "ìyàn ọdún méje ó tọ̀ ́ ilẹ̀ rẹ ? Tàbí ìwọ máa oṣù mẹ́ta níwájú àwọn ̀rẹ, nígbà wọn ó máa ? Tàbí ààrùn ìparun ọjọ́ mẹ́ta ó ilẹ̀ rẹ? ó nísinsin yìí, o mọ èsì èmi ó padà tọ ẹni ó rán mi."

14 Dafidi fún Gadi , "Ìyọnu ńlá mi. Jẹ́ a fi ara wa Olúwa ọwọ́; nítorí àánú rẹ̀ pọ̀; ó ṣe fi ènìyàn ọwọ́."

15 Olúwa rán ààrùn ìparun Israẹli láti òwúrọ̀ títí àkókò a , ẹgbẹ̀rún ̀àádọ́rin (70,000) ènìyàn nínú àwọn ènìyàn náà láti Dani títí fi Beerṣeba. 16 Nígbà angẹli náà nawọ́ rẹ̀ Jerusalẹmu láti pa á run, Olúwa káàánú nítorí ibi náà, ó sọ fún angẹli ń pa àwọn ènìyàn náà run , "Ó , ọwọ́ rẹ dúró wàyí!" Angẹli Olúwa náà níbi ìpakà Arauna ará Jebusi.

17 Dafidi fún Olúwa nígbà ó angẹli ń kọlu àwọn ènìyàn , "ó, èmi ti ṣẹ̀, èmi ti hùwà búburú ṣùgbọ́n àwọn àgùntàn wọ̀nyí, kín ni wọ́n ha ṣe? Jẹ́ ọwọ́ rẹ, èmi bẹ̀ ́, ó lára mi àti ìdílé baba mi."

Pẹpẹ ibi ìpakà Ornani

18 Gadi tọ Dafidi ọjọ́ náà, ó fún un , "Gòkè, tẹ́ pẹpẹ kan fún Olúwa lórí ilẹ̀ ìpakà Arauna ará Jebusi." 19 Gẹ́gẹ́ ̀rọ̀ Gadi, Dafidi gòkè lọ Olúwa ti pa á àṣẹ. 20 Arauna , ó ọba àti àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀ ń bọ̀ lọ́dọ̀ rẹ̀, Arauna jáde, ó wólẹ̀ níwájú ọba ó dojú rẹ̀ bolẹ̀.

21 Arauna , "Nítorí kín ni olúwa mi ọba ṣe tọ ìránṣẹ́ rẹ̀ ?"

Dafidi dáhùn , "Láti ra ibi ìpakà rẹ lọ́wọ́ rẹ, láti tẹ́ pẹpẹ kan fún Olúwa, ààrùn ìparun lára àwọn ènìyàn náà."

22 Arauna fún Dafidi , "Jẹ́ olúwa mi ọba ó èyí ó dára lójú rẹ̀, o fi í ẹbọ, ó, màlúù nìyìí láti fi ṣe ẹbọ sísun, àti ohun èlò ìpakà, àti ohun èlò mìíràn ti màlúù fún igi. 23 Gbogbo nǹkan wọ̀nyí ni Arauna fi fún ọba, ọba." Arauna fún ọba , "Olúwa Ọlọ́run rẹ ó gba ọrẹ rẹ."

24 Ọba fún Arauna , "Bẹ́̀ kọ́; ṣùgbọ́n èmi ó á iye kan lọ́wọ́ rẹ, ó ti ó ṣe; bẹ́̀ ni èmi yóò fi èyí èmi náwó fún, ẹbọ sísun Olúwa Ọlọ́run mi."

Dafidi ra ibi ìpakà náà, àti àwọn màlúù náà àádọ́ta ṣékélì fàdákà. 25 Dafidi tẹ́ pẹpẹ kan níbẹ̀ Olúwa, ó ẹbọ sísun àti ti ìlàjà. Olúwa gbọ́ ̀bẹ̀ fún ilẹ̀ náà, ààrùn náà kúrò Israẹli.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também