Pular para o conteúdo
Publicidade

2 Samuẹli 3

Abneri àti Iṣboṣeti

1 Ogun náà pẹ́ títí láàrín ìdílé Saulu àti ìdílé Dafidi: agbára Dafidi ń pọ̀ i, ṣùgbọ́n ìdílé Saulu ń rẹ̀yìn i.

2 3.2-5: 1Ki 3.1-4. Dafidi ọmọkùnrin Hebroni:

Amnoni ni àkọ́rẹ̀ Ahinoamu ará Jesreeli fún un.

3 Èkejì rẹ̀ ni Kileabu, Abigaili aya Nabali ará Karmeli fún un;

̀kẹta ni Absalomu ọmọ Maaka ọmọbìnrin Talmai ọba Geṣuri fún un.

4 ̀kẹrin ni Adonijah ọmọ Haggiti;

àti ̀karùnún ni Ṣefatia ọmọ Abitali;

5 ̀kẹfà ni Itreamu, Egla aya Dafidi fún un.

Wọ̀nyí ni a fún Dafidi ni Hebroni.

6 Ó ṣe, nígbà ogun láàrín ìdílé Saulu àti ìdílé Dafidi, Abneri alágbára ìdílé Saulu. 7 Saulu ti àlè kan, orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Rispa, ọmọbìnrin Aiah: Iṣboṣeti bi Abneri léèrè , "Èéṣe ìwọ fi wọlé tọ àlè baba mi lọ."

8 Abneri bínú gidigidi nítorí ̀rọ̀ wọ̀nyí ti Iṣboṣeti sọ fún un, ó , "Èmi jẹ́ orí ajá ti Juda ? Di òní yìí ni mo ṣàánú fún ìdílé Saulu baba rẹ, àti fún àwọn arákùnrin rẹ̀, àti fún àwọn ̀rẹ́ rẹ̀, èmi fi ́ Dafidi lọ́wọ́, ìwọ ̀ṣẹ̀ lọ́rùn nítorí obìnrin yìí lónìí? 9 Bẹ́̀ ni Ọlọ́run ó ṣe Abneri, àti bẹ́̀ lọ pẹ̀, Olúwa ti búra fún Dafidi, èmi ṣe bẹ́̀ fún un. 10 Láti ìjọba náà kúrò ìdílé Saulu, àti láti gbé ìtẹ́ Dafidi kalẹ̀ lórí Israẹli, àti lórí Juda, láti Dani títí ó fi Beerṣeba." 11 Òun Abneri lóhùn kan nítorí ó bẹ̀rẹ̀.

12 Abneri rán àwọn oníṣẹ́ Dafidi nítorí rẹ̀ , "Ti ta ni ilẹ̀ náà ń ṣe? mi ṣe àdéhùn, èmi yóò si gbogbo Israẹli tọ̀ ́ ."

13 Òun , "Ó dára, èmi ó ṣe àdéhùn, ṣùgbọ́n ohun kan ni èmi ó béèrè lọ́wọ́ rẹ, èyí ni , ìwọ yóò ojú mi, àfi ìwọ kọ́ Mikali ọmọbìnrin Saulu , nígbà ìwọ , láti ojú mi." 14 Dafidi rán àwọn ìránṣẹ́ Iṣboṣeti ọmọ Saulu , "Fi Mikali obìnrin mi mi lọ́wọ́, ẹni èmi ti fi ọgọ́rùn-ún awọ iwájú orí àwọn Filistini fẹ́."

15 Iṣboṣeti ránṣẹ́, ó gbà á lọ́wọ́ ọkùnrin a ń Paltieli ọmọ Laiṣi. 16 Ọkọ rẹ̀ ń a lọ, ó ń rìn, ó ń sọkún lẹ́yìn rẹ̀ títí ó fi Bahurimu Abneri fún un , "Padà sẹ́yìn!" Òun padà.

Abneri Dafidi Hebroni

17 Abneri àwọn àgbàgbà Israẹli sọ̀rọ̀ , "̀yin ti ń ṣe àfẹ́Dafidi ìgbà àtijọ́, láti jẹ ọba lórí yín. 18 Ǹjẹ́ ṣe, nítorí Olúwa ti sọ fún Dafidi , Láti ọwọ́ Dafidi ìránṣẹ́ mi mi ó gba Israẹli ènìyàn mi kúrò lọ́wọ́ àwọn Filistini àti lọ́wọ́ gbogbo àwọn ̀a wọn.’ "

19 Abneri sọ̀rọ̀ létí Benjamini: Abneri lọ sọ létí Dafidi Hebroni, gbogbo èyí ó dára lójú Israẹli, àti lójú gbogbo ilé Benjamini. 20 Abneri tọ Dafidi Hebroni, ogún ọmọkùnrin lọ pẹ̀rẹ̀ Dafidi ṣe àsè fún Abneri àti fún àwọn ọmọkùnrin ó pẹ̀rẹ̀. 21 Abneri fún Dafidi , "Èmi ó dìde, èmi ó lọ, èmi ó gbogbo Israẹli jọ sọ́dọ̀ ọba olúwa mi, wọn ó a ṣe àdéhùn, ìwọ ó jẹ ọba gbogbo wọn ọkàn rẹ ti ń fẹ́." Dafidi rán Abneri lọ; òun lọ àlàáfíà.

Joabu gbọ́ nípa wíwá Abneri Hebroni

22 ó, àwọn ìránṣẹ́ Dafidi àti Joabu ti ibi ìlépa ẹgbẹ́ ogun kan bọ̀, wọ́n ìkógun púpọ̀ bọ̀; ṣùgbọ́n Abneri lọ́dọ̀ Dafidi Hebroni; nítorí òun ti rán an lọ, òun ti lọ àlàáfíà. 23 Nígbà Joabu àti gbogbo ogun ó pẹ̀rẹ̀ , wọ́n sọ fún Joabu Abneri, ọmọ Neri ti tọ ọba , òun ti rán an lọ, ó ti lọ àlàáfíà.

24 Joabu tọ ọba , ó sọ , "ni ìwọ ṣe yìí? ó, Abneri tọ̀ ́ ; èéha ti ṣe ìwọ fi rán an lọ? Òun ti lọ. 25 Ìwọ mọ Abneri ọmọ Neri, ó láti tàn ́ jẹ ni, àti láti mọ ìjáde lọ rẹ, àti wíwọlé rẹ́ àti láti mọ gbogbo èyí ìwọ ń ṣe."

Joabu pa Abneri

26 Nígbà Joabu jáde kúrò lọ́dọ̀ Dafidi, ó rán àwọn ìránṣẹ́ láti lépa Abneri, wọ́n é padà láti ibi kànga Sira, Dafidi mọ̀. 27 Abneri padà Hebroni, Joabu a tẹ̀ láàrín ojú ̀láti a sọ̀rọ̀ àlàáfíà, ó gún un níbẹ̀ lábẹ́ inú, ó , nítorí ̀jẹ̀ Asaheli arákùnrin rẹ̀.

28 Lẹ́yìn ìgbà Dafidi gbọ́ , ó , "Èmi àti ìjọba mi jẹ́ aláìlẹ́bi níwájú Olúwa títí láé, ti ̀jẹ̀ Abneri ọmọ Neri, 29 jẹ́ ó orí Joabu, àti orí gbogbo ìdílé baba rẹ̀; a fẹ́ ẹni ó ààrùn ìsun, tàbí adẹ́tẹ̀, tàbí ẹni ń tẹ ̀, tàbí ẹni a ó fi idà pa, tàbí ẹni ó ṣe aláìní oúnjẹ ilé Joabu."

30 (Joabu àti Abiṣai arákùnrin rẹ̀ pa Abneri, nítorí òun ti pa Asaheli arákùnrin wọn Gibeoni ogun.)

31 Dafidi fún Joabu àti fún gbogbo ènìyàn ń bẹ lọ́dọ̀ rẹ̀ , "fa aṣọ yín ya, ̀yin aṣọ ̀fọ̀, ̀yin sọkún níwájú Abneri." Dafidi ọba tìkára rẹ̀ tẹ̀pósí rẹ̀. 32 Wọ́n sin Abneri Hebroni, ọba gbé ohùn rẹ̀ sókè, ó sọkún ibojì Abneri; gbogbo àwọn ènìyàn náà sọkún.

33 Ọba sọkún lórí Abneri, ó ,

"Ǹjẹ́ Abneri ó yẹ ó aṣiwèrè?

34 A à ́ lọ́wọ́,

bẹ́̀ ni a kan ẹsẹ̀ rẹ àbà.

Gẹ́gẹ́ ènìyàn ń ṣubú níwájú àwọn ìkà ènìyàn, bẹ́̀ ni ìwọ ṣubú."

Gbogbo àwọn ènìyàn náà tún sọkún lórí rẹ̀.

35 Nígbà gbogbo ènìyàn láti gba Dafidi ìyànjú ó jẹun, nígbà ọjọ́ ń bẹ, Dafidi búra , "Bẹ́̀ ni Ọlọ́run ó ṣe mi àti bẹ́̀ lọ, èmi yóò tọ́ oúnjẹ , tàbí nǹkan mìíràn títí oòrùn yóò fi wọ̀!"

36 Gbogbo àwọn ènìyàn kíyèsi i, ó dára lójú wọn, gbogbo èyí ọba ṣe dára lójú gbogbo àwọn ènìyàn náà. 37 Gbogbo àwọn ènìyàn náà àti gbogbo Israẹli mọ̀ lọ́jọ́ náà , í ṣe ìfẹ́ ọba láti pa Abneri ọmọ Neri.

38 Ọba fún àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀ , "̀yin mọ̀ olórí àti ẹni ńlá kan ni ó ṣubú lónìí Israẹli. 39 Èmi ṣe aláìlágbára lónìí, ó tilẹ̀ jẹ́ a fi èmi jẹ ọba; àwọn ọkùnrin wọ̀nyí ọmọ Seruiah le lọ: Olúwa ni yóò san án fún ẹni ó ṣe ibi gẹ́gẹ́ ìwà búburú rẹ̀!"

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também