Pular para o conteúdo
Publicidade

1 Kronika 15

Wọ́n gbé àpótí ̀Jerusalẹmu

1 15.1–16.3: 2Sa 6.12-19. Lẹ́yìn ìgbà Dafidi ti kọ́ ilé fún ara rẹ̀ ìlú Dafidi. Ó fi ààyè sílẹ̀ fún àpótí ̀Ọlọ́run ó pàgọ́ fún un. 2 Nígbà náà Dafidi , ẹnìkan àyàfi àwọn ọmọ Lefi ni ó gbé àpótí ̀Ọlọ́run, nítorí Olúwa yàn wọ́n láti gbé àpótí ̀Olúwa àti láti máa ṣe ìránṣẹ́ níwájú rẹ̀ títí láé.

3 Dafidi gbogbo àwọn ọmọ Israẹli jọ Jerusalẹmu láti gbé àpótí ̀Olúwa ibi ó ti pèsè sílẹ̀ fún un.

4 Wọ̀nyí ni àwọn ọmọ Aaroni àti àwọn ọmọ Lefi Dafidi péjọ papọ̀.

5 Ọgọ́nínú àwọn ọmọ Kohati;

Urieli olórí àti àwọn ẹbí rẹ̀.

6 Igba ó ogún nínú àwọn ọmọ Merari;

Asaiah olórí àti àwọn ẹbí rẹ̀.

7 Àádóje nínú àwọn ọmọ Gerṣoni;

Joẹli olórí àti àwọn ẹbí rẹ̀.

8 Igba nínú àwọn ọmọ Elisafani;

Ṣemaiah olórí àti àwọn ẹbí rẹ̀.

9 Ọgọ́rin nínú àwọn ọmọ Hebroni;

Elieli olórí àti àwọn ẹbí rẹ̀.

10 Méjìléláàádọ́nínú àwọn ọmọ Usieli;

Amminadabu olórí àti àwọn ẹbí rẹ̀.

11 Dafidi ránṣẹ́ pe Sadoku, Abiatari wọ́n jẹ́ àlùfáà, àti Urieli, Asaiah. Joẹli, Ṣemaiah, Elieli àti Amminadabu wọ́n jẹ́ Lefi. 12 Ó fi fún wọn , "̀yin ni olórí àwọn ìdílé Lefi; ̀yin àti àwọn Lefi ènìyàn yín, ya ara yín mímọ́ gbé àpótí ̀Olúwa, Ọlọ́run Israẹli, lọ ibi ti pèsè sílẹ̀ fún un. 13 Nítorí ̀yin ọmọ Lefi gbe gòkè ìgbà àkọ́kọ́ ti Olúwa Ọlọ́run fi ìbínú rẹ̀ ko . Àwa ṣe ìwádìí lọ́wọ́ rẹ̀ nípa a ti ń ṣe é gẹ́gẹ́ ́a sílẹ̀." 14 Bẹ́̀ ni àwọn àlùfáà àti àwọn Lefi ya ara wọn mímọ́ láti gbé àpótí ̀Olúwa gòkè , Ọlọ́run Israẹli. 15 Nígbà náà ni àwọn Lefi gbé àpótí ̀Ọlọ́run pẹ̀̀èjìká wọn gẹ́gẹ́ Mose ti pa á láṣẹ gẹ́gẹ́ ̀rọ̀ Olúwa.

16 Dafidi sọ fún àwọn olórí àwọn Lefi láti yan àwọn arákùnrin wọn gẹ́gẹ́ akọrin láti kọ orin ayọ̀, pẹ̀àwọn ohun èlò orin olókùn, dùùrù, àti símbálì.

17 Bẹ́̀ ni àwọn Lefi yan Hemani ọmọ Joẹli; àti nínú àwọn arákùnrin rẹ̀, Asafu ọmọ Berekiah, àti nínú àwọn ọmọ Merari arákùnrin wọn, Etani ọmọ Kuṣaiah; 18 àti pẹ̀wọn àwọn arákùnrin wọn a yàn olùrànlọ́wọ́ wọn: Sekariah, Jaasieli, Ṣemiramotu, Jehieli, Unni, Eliabu, Benaiah, Maaseiah, Mattitiah, Elifelehu, Mikimeiah, àti Obedi-Edomu àti Jeieli, àwọn aṣọ́bodè.

19 Àwọn akọrin ni Hemani, Asafu, àti Etani ti àwọn ti kimbali idẹ ń dún kíkan; 20 Sekariah, Asieli, Ṣemiramotu, Jehieli, àti Unni, Eliabu, Maaseiah àti Benaiah àwọn ó gbọdọ̀ ta ohun èlò orin olókùn gẹ́gẹ́ alamoti, 21 àti Mattitiah, Elifelehu, Mikneiah, Obedi-Edomu, Jeieli àti Asasiah ni ó láti ta ohun èlò olóhùn gooro, láti darí gẹ́gẹ́ ṣeminiti. 22 Kenaniah olórí àwọn ará Lefi ni ó ìkáwọ́ orin èyí ni ojúṣe nítorí ó mòye nípa rẹ̀.

23 Berekiah àti Elkana ni ó gẹ́gẹ́ olùṣọ́fún àpótí ̀. 24 Ṣebaniah, Jehoṣafati, Netaneli, Amasai, Sekariah, Benaiah àti Elieseri àwọn àlùfáà, o ń fún ìpè níwájú àpótí ̀Ọlọ́run. Obedi-Edomu àti Jehiah ni ó gbọdọ̀ jẹ́ olùṣọ́fún àpótí ̀.

25 Bẹ́̀ ni Dafidi àti àwọn àgbàgbà Israẹli àti àwọn olórí ẹgbẹẹgbẹ̀rún lọ láti gbé àpótí ̀ti májẹ̀Olúwa láti ilé Obedi-Edomu, pẹ̀inú dídùn. 26 Nítorí Ọlọ́run ràn wọ́n lọ́wọ́ àwọn ará Lefi ẹni ó gbé àpótí ̀ti májẹ̀Olúwa, akọ màlúù méje pẹ̀àgbò méje láti fi ṣé ìrúbọ. 27 Dafidi wọ efodu; aṣọ ìgúnwà ̀gbọ̀ dáradára, àti gbogbo àwọn ọmọ Lefi ń ru àpótí ̀náà, àti àwọn akọrin, àti Kenaniah olórí pẹ̀àwọn akọrin. Dafidi wọ aṣọ ìgúnwà funfun. 28 Bẹ́̀ ni gbogbo Israẹli gbé àpótí ̀àti májẹ̀Olúwa gòkè pẹ̀ariwo, pẹ̀àyíká ìhó ayọ̀ àti láti fọn fèrè ti ìpè, àti kimbali, àti láti ta ohun èlò orin olókùn àti dùùrù olóhùn gooro.

29 àpótí ̀Olúwa ti ń wọ ìlú ńlá Dafidi, Mikali ọmọbìnrin Saulu ń láti ojú fèrèsé nígbà ó ọba Dafidi ń , ó ń ṣe àjọyọ̀, ó kẹ́gàn rẹ̀ ọkàn rẹ̀.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também