Pular para o conteúdo
Publicidade

1 Kronika 14

Ilé àti ìdílé Dafidi

1 14.1,2: 2Sa 5.11,12. Nísinsin yìí Hiramu àti ọba Tire rán oníṣẹ́ Dafidi, àti pẹ̀igi kedari pẹ̀àwọn ̀mọ̀àti gbẹ́nàgbẹ́láti kọ́ ààfin fún un. 2 Dafidi mọ Israẹli àti Olúwa ti fi òun ṣe ọba lórí Israẹli àti ìjọba rẹ̀ ga jùlọ nítorí ti àwọn ènìyàn rẹ̀.

3 14.3-7: 1Ki 3.5-8; 2Sa 5.14-16. Jerusalẹmu Dafidi ̀pọ̀ ìyàwó ó di baba àwọn ọmọ ọkùnrin púpọ̀ àti ọmọbìnrin. 4 Èyí ni orúkọ àwọn ọmọ náà wọ́n fún un níbẹ̀: Ṣammua, Ṣobabu, Natani, Solomoni, 5 Ibhari, Eliṣua, Elifeleti, 6 Noga, Nefegi, Jafia, 7 Eliṣama, Beeliada, àti Elifeleti.

Dafidi ṣẹ́gun àwọn ará Filistini

8 14.8-12: 2Sa 5.17-21. Nígbà àwọn ará Filistini gbọ́ a ti fi àmì òróró yàn Dafidi ọba lórí gbogbo Israẹli, wọ́n lọ sókè pẹ̀ipá láti a , ṣùgbọ́n Dafidi gbọ́ nípa rẹ̀ ó jáde lọ láti pàdé wọn. 9 Nísinsin yìí àwọn ará Filistini ti láti gbógun ti àfonífojì Refaimu; 10 Dafidi béèrè lọ́dọ̀ Ọlọ́run , "èmi ó gòkè tọ àwọn ará Filistini lọ ? Ìwọ ó ha fi wọ́n mi lọ́wọ́?"

Olúwa fún un , "Gòkè lọ èmi ó fi wọ́n lọ́wọ́."

11 Bẹ́̀ ni Dafidi àti àwọn ènìyàn rẹ̀ gòkè lọ Baali-Perasimu, níbẹ̀ ó kọlù wọ́n. Ó , "Gẹ́gẹ́ omi ya jáde, Ọlọ́run ti ya Dafidi lórí àwọn ̀mi pẹ̀ọwọ́ mi." Bẹ́̀ ni wọ́n ń ibẹ̀ Baali-Perasimu. 12 Àwọn ará Filistini ti fi àwọn òrìṣà wọn sílẹ̀ níbẹ̀. Dafidi pa á láṣẹ láti wọn nínú iná.

13 14.13-16: 2Sa 5.22-25. Lẹ́̀kan i àwọn ará Filistini gbógun wọ́n fọ́nká àfonífojì, 14 Bẹ́̀ ni Dafidi tún béèrè lọ́wọ́ Ọlọ́run, Ọlọ́run dalóhùn , "ṣe gòkè tààrà, ṣùgbọ́n wọn , wọn níwájú igi muliberi. 15 ó ṣe, ̀yin ti gbọ́ ìró ẹsẹ̀ orí òkè igi muliberi, jáde fún ogun, nítorí èyí yóò fihàn Ọlọ́run ti jáde níwájú rẹ láti kọlu àwọn ọmọ-ogun Filistini." 16 Bẹ́̀ ni Dafidi ṣe ohun Ọlọ́run ti pàṣẹ fún wọn, wọ́n kọlu àwọn ọmọ-ogun Filistini láti gbogbo ̀Gibeoni lọ Geseri.

17 Bẹ́̀ ni òkìkí Dafidi tàn gbogbo ilẹ̀ káàkiri, Olúwa gbogbo orílẹ̀-èdè bẹ̀rẹ̀.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também