Pular para o conteúdo
Publicidade

1 Kronika 22

1 Nígbà náà Dafidi , "Ilé Olúwa Ọlọ́run ni ó gbọdọ̀ níbí, àti pẹ̀pẹpẹ ẹbọ sísun fún Israẹli."

Ìmúrasílẹ̀ fún ilé a kọ́ fún ìsìn Ọlọ́run

2 Bẹ́̀ ni Dafidi pàṣẹ láti àwọn àjèjì ń gbé Israẹli jọ, àti lára wọn ni ó ti yan àwọn agbẹ́-òkúta láti gbé òkúta dáradára láti fi kọ́Ọlọ́run. 3 Dafidi pèsè ̀pọ̀lọpọ̀ iye irin láti fi ṣe ìṣó fún àwọn ìlẹ̀kùn ẹnu-ọ̀àti fún idẹ; àti fún òpó idẹ ni àìní ìwọ̀n. 4 Ó tún pèsè ̀pọ̀lọpọ̀ igi Kedari ó jẹ́ àìníye, nítorí àwọn ará Sidoni àti àwọn ará Tire ̀pọ̀lọpọ̀ igi kedari fún Dafidi.

5 Dafidi , "Ọmọ mi Solomoni ̀dọ́mọdé ni ó jẹ́ aláìní ìrírí, ilé a ó kọ́ fún Olúwa gbọdọ̀ jẹ́ títóbi jọjọ, ó òkìkí àti ògo jákèjádò gbogbo àwọn orílẹ̀-èdè. Nítorí náà ni èmi yóò ṣe pèsè sílẹ̀ fún un". Bẹ́̀ ni Dafidi ṣe ìpèsè sílẹ̀ lọ́pọ̀lọ́pọ̀ ó di ó .

6 Nígbà náà ó pe Solomoni ọmọ rẹ̀ ó sọ fun ó kọ́ ilé fún un Olúwa, Ọlọ́run Israẹli. 7 22.7-10: 2Sa 7.1-16; 1Ki 17.1-14.Dafidi fún Solomoni , "Ọmọ mi, mo ní-in ọkàn mi láti kọ́ ilé fún orúkọ Olúwa Ọlọ́run mi. 8 Ṣùgbọ́n ̀rọ̀ Olúwa tọ̀ , Ìwọ ti ta ̀jẹ̀ sílẹ̀ ̀pọ̀lọpọ̀, o ti ja ̀pọ̀ ogun ńlá ńlá, í ṣe ìwọ ni yóò kọ́ ilé fún orúkọ mi, nítorí ìwọ ti ta ̀jẹ̀ sílẹ̀ púpọ̀ lórí ilẹ̀ ojú mi. 9 Ṣùgbọ́n ìwọ yóò ọmọ yóò jẹ́ ọkùnrin onírẹ̀lẹ̀ àti onísinmi, Èmi yóò fún un ìsinmi láti ̀dọ̀ gbogbo àwọn ̀rẹ̀ lórí gbogbo ilẹ̀ yíká. Orúkọ rẹ̀ yóò máa jẹ́ Solomoni, Èmi yóò fi àlàáfíà àti ìdákẹ́ jẹ́́ fún Israẹli lásìkò ìjọba rẹ̀. 10 Òun ni ẹni náà yóò kọ́ ilé fún orúkọ mi. Yóò jẹ́ ọmọ mi, èmi yóò jẹ́ baba rẹ̀ èmi yóò fi ìdí ìtẹ́ ìjọba rẹ̀ múlẹ̀ lórí Israẹli láéláé.

11 "Nísinsin yìí, ọmọ mi, Olúwa pẹ̀rẹ, ìwọ ó àṣeyọrí o kọ́ ilé Olúwa Ọlọ́run rẹ, àti gẹ́gẹ́ ó ti sọ nípa rẹ. 12 Olúwa ó fún ni ọgbọ́n àti òye nígbà ó fi ́ ṣe aláṣẹ lórí Israẹli, bẹ́̀ ni ìwọ ó pa òfin Olúwa Ọlọ́run mọ́. 13 Nígbà náà ìwọ yóò àṣeyọrí ìwọ ṣe àkíyèsí láti àṣẹ àti ìdájọ́ àti òfin ti Olúwa ti fi fún Mose fun Israẹli ṣe. Bẹ́̀ ni ki ìwọ jẹ́ alágbára àti onígboyà. ṣè bẹ̀tàbí àyà ṣe ́.

14 "Èmi ti gba ìpọ́njú ńlá láti ṣe fún ilé Olúwa ̀kẹ́ márùn-ún tálẹ́ǹtì wúrà, àti ẹgbẹ̀rún ẹgbẹ̀rún tálẹ́ǹtì fàdákà, ìwọ̀n idẹ àti irin ó tóbi àìní ìwọ̀n, àti ìtì igi àti òkúta. Ìwọ tún le fi kún wọn. 15 Ìwọ ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn oníṣẹ́ ènìyàn: àwọn gbẹ́nàgbẹ́, àti àwọn oníṣọ̀òkúta àti àwọn agbẹ́-òkúta, àti gẹ́gẹ́ onírúurú ọlọ́gbọ́n ènìyàn gbogbo onírúurú iṣẹ́. 16 Nínú wúrà, fàdákà àti idẹ àti irin oníṣọ̀ìwọ̀n. Nísinsin yìí bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́, Olúwa pẹ̀rẹ."

17 Nígbà náà Dafidi pa á láṣẹ fún gbogbo àwọn àgbàgbà Israẹli láti ran Solomoni ọmọ rẹ̀ lọ́wọ́. 18 Ó , "Ṣé Olúwa Ọlọ́run rẹ pẹ̀rẹ? Òun ha ti fi ìsinmi fún lórí gbogbo ilẹ̀? Nítorí ó ti fi àwọn ń gbé ilẹ̀ náà mi lọ́wọ́ ó ti fi ìṣẹ́gun fún ilẹ̀ náà níwájú Olúwa àti níwájú àwọn ènìyàn. 19 Nísinsin yìí, ṣí ọkàn yin páyà àti àyà yín àti Olúwa Ọlọ́run yín. Bẹ́̀ ni kọ́ ibi mímọ́ fún Olúwa Ọlọ́run. Bẹ́̀ ni ìwọ ó le gbé àpótí ̀ti májẹ̀Olúwa àti ohun èlò mímọ́ ó jẹ́ ti Ọlọ́run, sínú ilé Olúwa a o kọ́ fún orúkọ Olúwa."

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também