Pular para o conteúdo
Publicidade

1 Kronika 6

Lefi

1 6.1-15: Gẹ 46.11; Ek 6.16-20; Nu 3.2. Àwọn ọmọ Lefi:

Gerṣoni, Kohati àti Merari.

2 Àwọn ọmọ Kohati:

Amramu, Isari, Hebroni, àti Usieli.

3 Àwọn ọmọ Amramu:

Aaroni, Mose àti Miriamu.

Àwọn ọmọkùnrin Aaroni:

Nadabu, Abihu, Eleasari àti Itamari.

4 Eleasari jẹ́ baba Finehasi,

Finehasi baba Abiṣua

5 Abiṣua baba Bukki,

Bukki baba Ussi,

6 Ussi baba Serahiah,

Serahiah baba Meraioti,

7 Meraioti baba Amariah,

Amariah baba Ahitubu

8 Ahitubu baba Sadoku,

Sadoku baba Ahimasi,

9 Ahimasi baba Asariah,

Asariah baba Johanani,

10 Johanani baba Asariah.

(Òhun ni ó sìn gẹ́gẹ́ àlùfáà nínú ilé Olúwa Solomoni kọ́ Jerusalẹmu).

11 Asariah baba Amariah

Amariah baba Ahitubu

12 Ahitubu baba Sadoku.

Sadoku baba Ṣallumu,

13 Ṣallumu baba Hilkiah,

Hilkiah baba Asariah,

14 Asariah baba Seraiah,

pẹ̀Seraiah baba Josadaki.

15 A Josadaki lẹ́nígbà Olúwa Juda àti Jerusalẹmu kúrò ìlú nípasẹ̀ Nebukadnessari.

16 Àwọn ọmọ Lefi:

Gerṣoni, Kohati àti Merari.

17 Wọ̀nyí ni àwọn orúkọ àwọn ọmọ Gerṣoni:

Libni àti Ṣimei.

18 Àwọn ọmọ Kohati:

Amramu, Isari, Hebroni àti Usieli.

19 Àwọn ọmọ Merari:

Mahili àti Muṣi.

Wọ̀nyí ni àwọn ìdílé ará Lefi a kọ ṣísẹ̀-n-tẹ̀gẹ́gẹ́ baba wọn.

20 Ti Gerṣoni:

Libni ọmọkùnrin rẹ̀, Jahati.

Ọmọkùnrin rẹ̀, Simma ọmọkùnrin rẹ̀, 21 Joah ọmọkùnrin rẹ̀,

Iddo ọmọkùnrin rẹ̀, Sera ọmọkùnrin rẹ̀

àti Jeaterai ọmọkùnrin rẹ̀.

22 Àwọn ìran ọmọ Kohati:

Amminadabu ọmọkùnrin rẹ̀, Kora ọmọkùnrin rẹ̀,

Asiri ọmọkùnrin rẹ̀. 23 Elkana ọmọkùnrin rẹ̀,

Ebiasafi ọmọkùnrin rẹ̀, Asiri ọmọkùnrin rẹ̀.

24 Tahati ọmọkùnrin rẹ̀, Urieli ọmọkùnrin rẹ̀,

Ussiah ọmọkùnrin rẹ̀ àti Saulu ọmọkùnrin rẹ̀.

25 Àwọn ìran ọmọ Elkana:

Amasai, Ahimoti

26 Elkana ọmọ rẹ̀, Sofai ọmọ rẹ̀

Nahati ọmọ rẹ̀, 27 Eliabu ọmọ rẹ̀,

Jerohamu ọmọ rẹ̀, Elkana ọmọ rẹ̀

àti Samuẹli ọmọ rẹ̀.

28 Àwọn ọmọ Samuẹli:

Joẹli àkọ́

àti Abijah ọmọ ẹlẹ́̀kejì.

29 Àwọn ìran ọmọ Merari:

Mahili, Libni ọmọ rẹ̀.

Ṣimei ọmọ rẹ̀, Ussa ọmọ rẹ̀.

30 Ṣimea ọmọ rẹ̀, Haggiah ọmọ rẹ̀

àti Asaiah ọmọ rẹ̀.

Ilé ti a kọ́ fún àwọn Olórin

31 Èyí àwọn ọkùnrin Dafidi a fi ìdí orin nínú ilé Olúwa lẹ́yìn àpótí ̀ti láti sinmi níbẹ̀. 32 Wọ́n jíṣẹ́ pẹ̀orin níwájú àgọ́ ìpàdé títí Solomoni fi kọ́ ilé Olúwa Jerusalẹmu. Wọ́n ṣe iṣẹ́ ìsìn wọn ìbámu pẹ̀ìlànà a fi lélẹ̀ fún wọn.

33 Wọ̀nyí ni àwọn ọkùnrin ó sìn pẹ̀ọmọ wọn.

Láti ̀dọ̀ àwọn ará Kohati:

Hemani olùkọrin,

ọmọ Joẹli, ọmọ Samuẹli,

34 ọmọ Elkana, ọmọ Jerohamu,

ọmọ Elieli, ọmọ Toha,

35 ọmọ Sufu, ọmọ Elkana,

ọmọ Mahati, ọmọ Amasai,

36 ọmọ Elkana, ọmọ Joẹli,

ọmọ Asariah, ọmọ Sefaniah,

37 ọmọ Tahati, ọmọ Asiri,

ọmọ Ebiasafi, ọmọ Kora,

38 ọmọ Isari, ọmọ Kohati,

ọmọ Lefi, ọmọ Israẹli;

39 Hemani darapọ̀ mọ́ Asafu, ẹni o sìn ọwọ́ ̀tún rẹ̀:

Asafu ọmọ Berekiah, ọmọ Ṣimea,

40 ọmọ Mikaeli, ọmọ Baaseiah,

ọmọ Malkiah 41 ọmọ Etini,

ọmọ Sera, ọmọ Adaiah,

42 ọmọ Etani, ọmọ Simma,

ọmọ Ṣimei, 43 ọmọ Jahati,

ọmọ Gerṣoni, ọmọ Lefi;

44 láti ìbákẹ́gbẹ́ wọn, àwọn ará Merari ọwọ́ òsì rẹ̀:

Etani ọmọ Kiṣi, ọmọ Abdi,

ọmọ Malluki, 45 ọmọ Haṣabiah,

ọmọ Amasiah, ọmọ Hilkiah,

46 ọmọ Amisi, ọmọ Bani,

ọmọ Ṣemeri, 47 ọmọ Mahili,

ọmọ Muṣi, ọmọ Merari,

ọmọ Lefi.

48 Àwọn Lefi ẹgbẹ́ wọn ni wọn yan àwọn iṣẹ́ yòókù ti àgọ́ fún, èyí í ṣe ilé Ọlọ́run. 49 Ṣùgbọ́n Aaroni àti àwọn ìran ọmọ rẹ̀ jẹ́ àwọn ó gbé ọrẹ kalẹ̀ lórí pẹpẹ ẹbọ sísun àti lórí pẹpẹ tùràrí ìbátan pẹ̀gbogbo ohun a ṣe Ibi Mímọ́ Jùlọ. Ṣíṣe ètùtù fún Israẹli, ìbámu pẹ̀gbogbo ohun Mose ìránṣẹ́ Ọlọ́run ti pàṣẹ.

50 Wọ̀nyí ni àwọn ìránṣẹ́ Aaroni:

Eleasari ọmọ rẹ̀, Finehasi ọmọ rẹ̀,

Abiṣua ọmọ rẹ̀, 51 Bukki ọmọ rẹ̀,

Ussi ọmọ rẹ̀, Serahiah ọmọ rẹ̀,

52 Meraioti ọmọ rẹ̀, Amariah ọmọ rẹ̀,

Ahitubu ọmọ rẹ̀, 53 Sadoku ọmọ rẹ̀

àti Ahimasi ọmọ rẹ̀.

54 6.54-81: Jo 21.1-42. Wọ̀nyí ni ibùgbé wọn a pín fún wọn gẹ́gẹ́ agbègbè wọn (a fi àwọn ìran ọmọ Aaroni lọ́wọ́ ó láti ̀Kohati, nítorí kèké alákọ́kọ́ jẹ́ tiwọn).

55 A fún wọn Hebroni Juda pẹ̀àyíká pápá oko tútù ilẹ̀ rẹ̀. 56 Ṣùgbọ́n àwọn pápá àti ìletò ó ìlú ńlá náà ni a fi fún Kalebu ọmọ Jefunne. 57 Bẹ́̀ ni àwọn ìran ọmọ Aaroni ni a fún Hebroni (ìlú ti ààbò), àti Libina, Jattiri, Eṣitemoa, 58 Hileni, Debiri, 59 Aṣani, Jutta àti Beti-Ṣemeṣi lápapọ̀ pẹ̀pápá oko tútù ilẹ̀ rẹ̀.

60 Àti láti inú ̀Benjamini, a fún wọn Gibeoni, Geba, Alemeti àti Anatoti lápapọ̀ pẹ̀pápá oko tútù ilẹ̀ wọn.

Àwọn ìlú wọ̀nyí, a pín láàrín àwọn ̀Kohati jẹ́ mẹ́tàlá gbogbo rẹ̀.

61 Ìyókù àwọn ìran ọmọ Kohati a pín ìlú mẹ́wàá fún láti àwọn ìdílé ti ààbọ̀ ̀Manase.

62 Àwọn ìran ọmọ Gerṣoni, ìdílé ni a pín ìlú mẹ́tàlá fún láti ̀àwọn ̀Isakari, Aṣeri àti Naftali, àti láti apá ̀Manase ó Baṣani.

63 Sebuluni àwọn ìran ọmọ Merari, ìdílé ìdílé, a pín ìlú méjìlá fún láti ̀Reubeni, Gadi àti Sebuluni.

64 Bẹ́̀ ni àwọn ọmọ Israẹli fún àwọn ará Lefi ìlú wọ̀nyí pẹ̀pápá oko tútù ilẹ̀ wọn.

65 Láti ̀Juda, Simeoni àti Benjamini ni a pín ìlú a ti dárúkọ wọn sẹ́yìn fún.

66 Lára àwọn ìdílé Kohati ni a fún ìlú láti ̀Efraimu gẹ́gẹ́ ìlú agbègbè wọn.

67 òkè orílẹ̀-èdè Efraimu, a fún wọn Ṣekemu (ìlú ńlá ti ààbò), àti Geseri 68 Jokimeamu, Beti-Horoni. 69 Aijaloni àti Gati-Rimoni lápapọ̀ pẹ̀pápá oko tútù ilẹ̀ wọn.

70 Pẹ̀láti apá ààbọ̀ ̀Manase àwọn ọmọ Israẹli fún Aneri àti Bileamu lápapọ̀ pẹ̀pápá oko tútù ilẹ̀ wọn, fún ìyókù àwọn ìdílé Kohati.

71 Àwọn ará Gerṣoni gbà nǹkan wọ̀nyí.

Láti ààbọ̀ ̀ti Manase wọ́n gba Golani Baṣani àti pẹ̀Aṣtarotu, lápapọ̀ pẹ̀pápá oko tútù wọn.

72 Láti ̀Isakari wọ́n gba Kedeṣi, Daberati 73 Ramoti àti Anenu, lápapọ̀ pẹ̀pápá oko tútù ilẹ̀ wọn.

74 Láti ̀Aṣeri wọ́n gba Maṣali, Abdoni, 75 Hukoki àti Rehobu lápapọ̀ pẹ̀pápá oko tútù ilẹ̀ wọn.

76 Pẹ̀láti ̀Naftali wọ́n gba Kedeṣi Galili, Hammoni àti Kiriataimu, lápapọ̀ pẹ̀pápá oko tútù ilẹ̀ wọn.

77 Àwọn ará Merari (ìyókù àwọn ará Lefi) gbà nǹkan wọ̀nyí.

Láti ̀Sebuluni wọ́n gba Jokneamu, Karta, Rimoni àti Tabori, lápapọ̀ pẹ̀ilẹ̀ pápá oko tútù wọn.

78 Láti ̀Reubeni rékọjá Jordani ìlà-oòrùn Jeriko wọ́n gba Beseri nínú aginjù Jahisa, 79 Kedemoti àti Mefaati, lápapọ̀ pẹ̀ilẹ̀ pápá oko tútù wọn.

80 Pẹ̀láti ̀Gadi wọ́n gba Ramoti Gileadi Mahanaimu, 81 Heṣboni àti Jaseri lápapọ̀ pẹ̀àwọn ilẹ̀ pápá oko tútù wọn.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também