Pular para o conteúdo
Publicidade

1 Kronika 12

Àwọn ̀gágun ó dúró ti Dafidi

1 Àwọn wọ̀nyí ni ọkùnrin ó ̀dọ̀ Dafidi Siklagi, nígbà ó kúrò níwájú Saulu ọmọ Kiṣi (wọ́n lára àwọn jagunjagun ẹni ó ràn án lọ́wọ́ láti ibi ìjà. 2 Wọ́n wọn pẹ̀ìtẹríba wọ́n lágbára láti ta ọfà tàbí láti ta kànnàkànnà òkúta ọwọ́ òsì tàbí ọwọ́ ̀tún, wọ́n jẹ́ ìbátan ọkùnrin Saulu láti ̀Benjamini):

3 Ahieseri olórí wọn àti Joaṣi àwọn ọmọ Ṣemaah ará Gibeah:

Jeṣieli àti Peleti ọmọ Asmafeti,

Beraka, Jehu ará Anatoti. 4 Àti Iṣmaiah ará Gibeoni, ọkùnrin alágbára kan lára àwọn ọgbọ̀n ẹni ó jẹ́ olórí nínú àwọn ọgbọ̀n;

Jeremiah, Jahasieli, Johanani, Josabadi ará Gedera, 5 Elusai, Jerimoti, Bealiah, Ṣemariah àti Ṣefatia ará Harufiti;

6 Elkana, Iṣiah, Asareeli, Joeseri àti Jaṣobeamu ará Kora;

7 àti Joẹla, àti Sebadiah àwọn ọmọ Jerohamu láti Gedori.

8 Díẹ̀ lára àwọn ará Gadi sọ́dọ̀ Dafidi ibi gíga aginjù. Wọ́n jẹ́ onígboyà ológun ó múra fún ogun ó lágbára láti di asà àti ẹṣin . Ojú wọn dàbí ojú kìnnìún, wọ́n yára àgbọ̀nrín lórí àwọn òkè.

9 Eseri jẹ́ ìjòyè,

Obadiah jẹ́ igbákejì akọgun, Eliabu ẹlẹ́̀kẹta,

10 Miṣimana ẹlẹ́̀kẹrin, Jeremiah ẹlẹ́̀karùnún

11 Attai ẹlẹ́̀kẹfà, Elieli èkeje,

12 Johanani ẹlẹ́̀kẹjọ Elsabadi ẹlẹ́̀kẹsàn-án

13 Jeremiah ẹlẹ́̀kẹwàá àti Makbannai ẹlẹ́̀kọkànlá.

14 Àwọn ará Gadi wọ́n jẹ́ olórí ogun; ẹni ó kéré jẹ́ àpapọ̀ ọgọ́rùn-ún, àti fún ẹni ó pọ̀fún ẹgbẹ̀rún (1,000). 15 Àwọn ni ẹni ó rékọjá Jordani oṣù àkọ́kọ́ nígbà ó kún bo gbogbo bèbè rẹ̀, wọ́n gbogbo àwọn ó ń gbé nínú àfonífojì, lọ ìlà-oòrùn àti níhà ìwọ̀-oòrùn.

16 Ìyókù ará Benjamini àti àwọn díẹ̀ ọkùnrin láti Juda lọ ̀dọ̀ Dafidi ibi gíga. 17 Dafidi lọ láti lọ pàdé wọn ó fún wọn , "sọ́dọ̀ mi lálàáfíà, láti ràn lọ́wọ́ mo ṣetán láti un yín ìṣọ̀kan pẹ̀mi ṣùgbọ́n láti mi fún àwọn ̀mi nígbà ọwọ́ mi mọ́ kúrò nínú ìwà agbára, Ọlọ́run àwọn baba wa ó ri ó ṣe ìdájọ́."

18 Nígbà náà ̀Mímọ́ wa sórí Amasai ìjòyè àwọn ọgbọ̀n, ó ,

"Tìrẹ ni àwa ń ṣe, ìwọ Dafidi!

Àwa pẹ̀rẹ, ìwọ ọmọ Jese!

Àlàáfíà, àlàáfíà fún ,

àti àlàáfíà fún àwọn ó ràn ó lọ́wọ́,

nítorí Ọlọ́run rẹ̀ yóò ràn ́ lọ́wọ́."

Bẹ́̀ ni Dafidi gbà wọ́n ó wọn jẹ olórí ẹgbẹ́ ogun.

19 Díẹ̀ nínú àwọn ọkùnrin Manase ̀dọ̀ Dafidi nígbà ó lọ pẹ̀àwọn ará Filistini láti Saulu . (Òun àti àwọn ọkùnrin rẹ̀ wọn ran ará Filistini lọ́wọ́ nítorí, lẹ́yìn tiwọn sọ̀rọ̀ papọ̀, àwọn olórí wọn rán wọn jáde, wọ́n , "Yóò jẹ́ ìparun fún wa ó padà tọ ̀rẹ̀ Saulu lọ.") 20 Nígbà Dafidi lọ Siklagi, àwọn wọ̀nyí ni ọkùnrin ti Manase ẹni ó sọ́dọ̀ rẹ̀. Adina, Josabadi, Jediaeli, Mikaeli, Josabadi, Elihu àti Siletai, àwọn olórí ìrẹ́pọ̀ ti ẹgbẹẹgbẹ̀rún Manase. 21 Wọ́n ran Dafidi lọ́wọ́ lórí ẹgbẹ́ ogun náà, nítorí gbogbo wọn ni akọni ènìyàn àwọn tún ni olórí nínú àwọn ọmọ-ogun rẹ̀. 22 Ọjọ́ ọjọ́ ni àwọn ọkùnrin láti ran Dafidi lọ́wọ́, títí ó fi àwọn ológun ńlá, ogun Ọlọ́run.

Àwọn tókù darapọ̀ pẹ̀Dafidi Hebroni

23 Àwọn wọ̀nyí ni iye ọkùnrin ó ti di ìhámọ́ra fún ogun àwọn ẹni ó sọ́dọ̀ Dafidi Hebroni láti ìjọba Dafidi padà ̀dọ̀ rẹ̀, gẹ́gẹ́ Olúwa ti sọ.

24 Ọkùnrin Juda, o ń gbé asà àti ̀kọ̀, ẹgbàáta lẹ́gbẹ̀rin (6,800) ó ti di ìhámọ́ra fún ogun.

25 Àwọn ọkùnrin Simeoni, akọni fún ogun jẹ́ ̀́dẹ́gbàárin ó ọgọ́rùn-ún (7,100);

26 àwọn ọkùnrin Lefi ẹgbàajì ó le ẹgbẹ̀ta (4,600), 27 pẹ̀Jehoiada, olórí ìdílé Aaroni pẹ̀ẹgbẹ̀rún mẹ́ta ó ̀́dẹ́gbẹ̀rin (3,700) ènìyàn, 28 àti Sadoku akọni ̀dọ́mọkùnrin, pẹ̀àwọn méjìlélógún ìjòyè láti ̀dọ̀ àwọn ìdílé rẹ̀;

29 àwọn arákùnrin Benjamini ìbátan ọkùnrin Saulu ẹgbẹ̀rún mẹ́ta (3,000), ̀pọ̀ nínú àwọn ẹni ó si olóòtítọ́ ilé Saulu títí di ìgbà náà;

30 àwọn arákùnrin Efraimu, ògbójú akọni, ènìyàn Ọlọ́run ni wọ́n nílé baba wọn ogún ẹgbẹ̀rún ó le ẹgbẹ̀rin (20,800);

31 àwọn ọkùnrin nínú ààbọ̀ ̀Manase, a yàn nípa orúkọ láti àti láti yan Dafidi gẹ́gẹ́ ọba, ẹgbàá mẹ́sàn (18,000).

32 Àti ti àwọn ọmọ Isakari, àwọn ẹni ó òye àkókò, láti mọ ohun Israẹli ìbá máa ṣe; olórí wọn jẹ́ ìgbà; àti gbogbo àwọn ìbátan wọn ń bẹ ìkáwọ́ wọn.

33 Àwọn ọkùnrin Sebuluni, àti àwọn jagunjagun ó ti nípa ogun múra fún ogun pẹ̀oríṣìíríṣìí ohun èlò ìjà, láti ran Dafidi lọ́wọ́ pẹ̀àwọn fi iyèméjì ṣe ìjólóòótọ́ wọn jẹ́ ẹgbàá mẹ́̀́dọ́gbọ̀n (50,000).

34 Àwọn ọkùnrin Naftali, ẹgbẹ̀rún (1,000) ìjòyè àpapọ̀ pẹ̀ẹgbàá méjìdínlógún (36,000). Ọkùnrin wọ́n gbé asà àti ̀kọ̀ wọn.

35 Àwọn ọkùnrin Dani, wọ́n ṣetán fún ogun ẹgbàá mẹ́tàlá (28,600).

36 Àwọn ọkùnrin Aṣeri, àwọn ó ti ìmọ̀ ogun múra fún ogun ̀kẹ́ méjì (40,000).

37 Láti ìlà-oòrùn Jordani, ọkùnrin Reubeni, Gadi, àti ìdajì ̀Manase, dìmọ́ra pẹ̀gbogbo onírúurú ohun èlò ìjà ̀kẹ́ mẹ́(120,000).

38 Gbogbo èyí ni àwọn ọkùnrin ológun ó fi ara wọn fún ogun láti ṣe iṣẹ́ fún nínú ẹgbẹ́.

Wọ́n Hebroni ó kún fún ìpinnu láti fi Dafidi jẹ́ ọba lórí gbogbo Israẹli. Gbogbo àwọn ìyókù lára àwọn ọmọ Israẹli jẹ́ onínú kan láti fi Dafidi jẹ ọba. 39 Àwọn ọkùnrin náà lo ọjọ́ mẹ́ta níbẹ̀ pẹ̀Dafidi, wọ́n jẹ, wọ́n ń mu, nítorí ìdílé wọn ti pèsè oúnjẹ fún wọn. 40 Àwọn aládùúgbò láti ̀jíjìn gẹ́gẹ́ Isakari, Sebuluni àti Naftali gbé oúnjẹ lórí kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́, lórí ràkunmí, àti lórí ìbáaka àti lórí màlúù, àní oúnjẹ ti ìyẹ̀fun, èso àjàrà gbígbẹ, èso ̀pọ̀tọ́, àkàrà dídùn, ọtí wáìnì, òróró, màlúù àti àgùntàn, nítorí ̀pọ̀lọpọ̀ ayọ̀ Israẹli.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também