Pular para o conteúdo
Publicidade

1 Kronika 26

Àwọn olùtọ́ẹnu ọnà

1 Àwọn ìpín àwọn olùtọ́ẹnu-ọ̀.

Láti ìran Kora:

Meṣelemiah ọmọ Kore, ̀kan lára àwọn ọmọ Asafu. 2 Meṣelemiah àwọn ọmọkùnrin:

Sekariah àkọ́, Jediaeli ẹlẹ́̀kejì,

Sebadiah ẹlẹ́̀kẹta, Jatnieli ẹlẹ́̀kẹrin,

3 Elamu ẹlẹ́̀karùnún, Jehohanani ẹlẹ́̀kẹfà

àti Elihoenai ẹlẹ́̀keje.

4 Obedi-Edomu ni àwọn ọmọkùnrin pẹ̀:

Ṣemaiah àkọ́, Jehosabadi ẹlẹ́̀kejì,

Joah ẹlẹ́̀kẹta, Sakari ẹlẹ́̀kẹrin,

Netaneli ẹlẹ́̀karùnún, 5 Ammieli ̀kẹfà,

Isakari èkeje àti Peulltai ̀kẹjọ.

(Nítorí Ọlọ́run ti bùkún Obedi-Edomu).

6 Ọmọ rẹ̀ Ṣemaiah àwọn ọmọkùnrin pẹ̀wọ́n jẹ́ olórí ìdílé baba a wọn nítorí wọ́n jẹ́ ọkùnrin lágbára. 7 Àwọn ọmọ Ṣemaiah:

Otni, Refaeli, Obedi àti Elsabadi;

àwọn ìbátan rẹ̀ Elihu àti Samakiah jẹ́ ọkùnrin alágbára.

8 Gbogbo wọ̀nyí ìran ọmọ Obedi-Edomu; àwọn àti ọmọkùnrin àti ìbátan wọn jẹ́ alágbára ọkùnrin pẹ̀ipá láti ṣe ìsìn náà. Ìran Obedi-Edomu méjìlélọ́gọ́ta ni gbogbo rẹ̀.

9 Meṣelemiah àwọn ọmọ àti àwọn ìbátan, ó jẹ́ alágbára méjìdínlógún ni gbogbo wọn.

10 Hosa ará Merari àwọn ọmọkùnrin:

Ṣimri alákọ́kọ́ o tilẹ̀ jẹ́ i ṣe àkọ́, baba a rẹ̀ ti yàn an àkọ́kọ́.

11 Hilkiah ẹlẹ́̀kejì, Tabaliah ̀kẹta

àti Sekariah ̀kẹrin.

Àwọn ọmọ àti ìbátan Hosa jẹ́ mẹ́tàlá ni gbogbo rẹ̀.

12 Ìpín wọ̀nyí ti àwọn olùtọ́ẹnu-ọ̀nípasẹ̀ olóyè ọkùnrin wọn, iṣẹ́ ìsìn fún jíjíṣẹ́ nínú ilé Olúwa, gẹ́gẹ́ ìbátan wọn ti ṣe. 13 Wọ́n ṣẹ́ kèké fún ẹnu-ọ̀kọ̀̀kan gẹ́gẹ́ àwọn ìdílé wọn ̀dọ́ àti arúgbó.

14 Kèké fún ẹnu-ọ̀ilà oòrùn bọ́ ̀dọ̀ Ṣelemiah.

Nígbà náà a kèké fún ọmọkùnrin rẹ̀ Sekariah, ọlọ́gbọ́n onímọ̀ràn, kèké fún ẹnu-ọ̀àríwá bọ́ ̀dọ̀ rẹ̀.

15 Kèké fún ẹnu-ọ̀ìhà gúúsù bọ́ ̀dọ̀ Obedi-Edomu, kèké fún ilé ìṣúra bọ́ ̀dọ̀ ọmọ rẹ̀.

16 Kèké fún ẹnu-ọ̀ìhà ìwọ̀-oòrùn àti Ṣaleketi ẹnu-ọ̀̀apá òkè bọ́ ̀dọ̀ Ṣuppimu àti Hosa.

Olùṣọ́ ̀olùṣọ́.

17 Àwọn ará Lefi mẹ́ó ọjọ́ kan ìhà ìlà-oòrùn,

mẹ́rin ọjọ́ kan ìhà àríwá,

mẹ́rin ọjọ́ kan ìhà gúúsù

àti méjì ̀̀kan ṣoṣo ilé ìṣúra.

18 ti ilé ẹjọ́ ìhà ìwọ̀-oòrùn, mẹ́rin ojú ̀àti méjì ilé ẹjọ́ fúnra rẹ̀.

19 Wọ̀nyí ni ìpín ti àwọn olùtọ́ẹnu-ọ̀wọ́n jẹ́ àwọn ìran ọmọ Kora àti Merari.

Àwọn afowópamọ́ àti àwọn òṣìṣẹ́ ìyókù

20 Láti inú àwọn ọmọ Lefi, Ahijah ni ó lórí ìṣúra ti ilé Ọlọ́run àti lórí ìṣúra nǹkan wọ̀n-ọn-nì a mímọ́.

21 Àwọn ìran ọmọ Laadani wọn jẹ́ ará Gerṣoni nípasẹ̀ Laadani àti wọn jẹ́ àwọn olórí àwọn ìdílé ó jẹ́ ti Laadani ará Gerṣoni ni Jehieli. 22 Àwọn ọmọ Jehieli, Setamu àti arákùnrin rẹ̀ Joẹli. Wọ́n ṣalábojútó ilé ìṣúra ti ilé ìṣúra ti ilé Olúwa.

23 Láti ̀dọ̀ àwọn ará Amramu, àwọn ará Isari, àwọn ará Hebroni àti àwọn ará Usieli.

24 Ṣubaeli, ìran ọmọ Gerṣomu ọmọ Mose jẹ́ olórí ó bojútó ilé ìṣúra. 25 Àwọn ìbátan rẹ̀ nípasẹ̀ Elieseri: Rehabiah ọmọ rẹ̀, Jeṣaiah ọmọ rẹ̀, Joramu ọmọ rẹ̀, Sikri ọmọ rẹ̀, Ṣelomiti ọmọ rẹ̀.

26 Ṣelomiti àti àwọn ìbátan rẹ̀ jẹ́ alábojútó ilé ìṣúra fún àwọn ohun à ti sọ́tọ̀ nípa ọba Dafidi, nípasẹ̀ àwọn olórí àwọn ìdílé wọ́n jẹ́ alákòóso ̀rọ̀̀rún àti nípasẹ̀ alákòóso ọmọ-ogun mìíràn. 27 Díẹ̀ nínú ìkógun wọ́n nínú ogun ni wọ́n sọ́tọ̀ fún títún ilé Olúwa ṣe. 28 Pẹ̀gbogbo nǹkan a sọ́tọ̀ láti ̀dọ̀ Samuẹli aríran láti nípasẹ̀ Saulu ọmọ Kiṣi, Abneri ọmọ Neri àti Joabu ọmọ Seruiah gbogbo ohun a sọ́tọ̀ abẹ́ ìtọ́Ṣelomiti àti àwọn ìbátan rẹ̀.

29 Láti ̀dọ̀ àwọn Isari:

Kenaniah àti àwọn ọmọ rẹ̀ ni a pín iṣẹ́ ìsìn fún kúrò apá ilé Olúwa, gẹ́gẹ́ àwọn oníṣẹ́ àti àwọn adájọ́ lórí Israẹli.

30 Láti ̀dọ̀ àwọn Hebroni:

Haṣabiah àti àwọn ìbátan rẹ̀ ̀́dẹ́gbẹ̀sán (17,000) ọkùnrin alágbára ó dúró ni Israẹli, ìhà ìwọ̀-oòrùn Jordani fún gbogbo iṣẹ́ Olúwa àti fún iṣẹ́ ọba. 31 ti àwọn ará Hebroni, Jeriah jẹ́ olóyè wọn gẹ́gẹ́ ìwé ìrántí ìtàn ìdílé láti ̀dọ̀ baba ńlá wọn, ti ìdílé wọn.

ọdún kẹrin ìjọba Dafidi, a ṣe ìwádìí nínú ìwé ìrántí, àwọn ọkùnrin alágbára láàrín àwọn ará Hebroni ni a Jaseri Gileadi. 32 Jeriah ẹgbẹ̀rún méjì ó ̀́dẹ́gbẹ̀rin (2,700) ìbátan, wọn jẹ́ ọkùnrin alágbára àti olórí àwọn ìdílé ọba Dafidi fi wọ́n ṣe àkóso lórí àwọn ará Reubeni àwọn ará Gadi àti ààbọ̀ ̀ti Manase fún gbogbo ̀rọ̀ ó jọ mọ́ ti Ọlọ́run àti fún ̀ràn ti ọba.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também