Pular para o conteúdo
Publicidade

1 Kronika 19

Dafidi ṣẹ́gun àwọn ara Ammoni

1 19.1-19: 2Sa 10.1-19. àkókò , Nahaṣi ọba àwọn ará Ammoni , ọmọ rẹ̀ rọ́rẹ̀ gẹ́gẹ́ ọba. 2 Dafidi èmi yóò fi inú rere hàn Hanuni ọmọ Nahaṣi, nítorí baba a rẹ̀ fi inú rere hàn mi. Bẹ́̀ ni, Dafidi rán àwọn aṣojú lọ láti lọ fi ìbá kẹ́dùn rẹ̀ hàn Hanuni ti baba a rẹ̀.

Nígbà àwọn ọkùnrin Dafidi ̀dọ̀ Hanuni ilẹ̀ àwọn ará Ammoni láti fi ìbá kẹ́dùn rẹ̀ hàn i. 3 Àwọn ọkùnrin ọlọ́ti Ammoni sọ fún Hanuni , "Ṣé ìwọ Dafidi ń bu ọlá fún baba rẹ nípa rírán àwọn olùtùnú ? Ṣé àwọn ọkùnrin rẹ̀ ̀dọ̀ rẹ láti rìn àti láti í ṣubú, àti láti ṣe ayọ́lẹ̀ilẹ̀ náà." 4 Bẹ́̀ ni Hanuni fi ipá àwọn ọkùnrin Dafidi, irun wọn, wọ́n ̀wọn kúrò àárín ìdí rẹ̀, ó rán wọn lọ.

5 Nígbà ẹnìkan , ó sọ fún Dafidi nípa àwọn ọkùnrin rẹ̀, ó rán àwọn ìránṣẹ́ láti lọ wọn, nítorí wọ́n ti di rírẹ̀ sílẹ̀ gidigidi. Ọba pe, "Dúró Jeriko títí irùngbọ̀n yín yóò fi , nígbà náà padà ".

6 Nígbà àwọn ará Ammoni ri wọ́n ti di ̀ṣẹ̀ ihò imú Dafidi, Hanuni àti àwọn ará Ammoni rán ẹgbẹ̀rún (1,000) tálẹ́ǹtì fàdákà láti gba iṣẹ́ àwọn kẹ̀kẹ́ àti àwọn agun-kẹ̀kẹ́ láti Aramu-Naharaimu, Siria Maaka àti Soba. 7 Wọ́n gba iṣẹ́ ẹgbẹ̀rin méjìlélọ́gbọ̀n (32,000) kẹ̀kẹ́ àti agun-kẹ̀kẹ́ àti ọba Maaka pẹ̀àwọn ̀wọ́ ọmọ-ogun rẹ̀ ó pàgọ́ ̀Medeba, nígbà àwọn ará Ammoni kójọpọ̀ láti ìlú wọn, wọ́n jáde lọ fún ogun.

8 gbígbọ́ eléyìí, Dafidi rán Joabu jáde pẹ̀gbogbo àwọn ọmọ-ogun ọkùnrin ó le . 9 Àwọn ọmọ Ammoni jáde , wọ́n tẹ́ ogun ẹnu odi ìlú ńlá wọn, nígbà àwọn ọba ó , fún rara wọn ni orílẹ̀-èdè ó ṣí sílẹ̀.

10 Joabu ri àwọn ìlà ogun níwájú àti ̀yìn òun, bẹ́̀ ni o mu àwọn ọmọ-ogun ó dára Israẹli, o tẹ́ ogun wọn àwọn ará Siria. 11 Ó fi ìyókù àwọn ọkùnrin náà abẹ́ àkóso Abiṣai arákùnrin rẹ̀, a tẹ́ wọn wọn dojúkọ àwọn ará Ammoni. 12 Joabu àwọn ará Siria le fún mi, nígbà náà, ìwọ ni o gbà ; ṣùgbọ́n àwọn ará Ammoni le fún , nígbà náà èmi yóò gbà ́. 13 Jẹ́ alágbára jẹ́ a pẹ̀ìgboyà fún àwọn ènìyàn wa àti àwọn ìlú ńlá ti Ọlọ́run wa. Olúwa yóò ṣe ohun ó dára ojú rẹ̀.

14 Nígbà náà Joabu àti àwọn ọmọ-ogun pẹ̀rẹ̀ lọ síwájú láti lọ pẹ̀àwọn ará Siria. Wọ́n sálọ kúrò níwájú rẹ̀. 15 Nígbà ti àwọn ará Ammoni ri àwọn ará Siria ń sálọ, àwọn náà sálọ kúrò níwájú arákùnrin rẹ̀ Abiṣai. Wọ́n wọ inú ìlú ńlá lọ. Bẹ́̀ ni Joabu padà lọ Jerusalẹmu.

16 Lẹ́yìn ìgbà àwọn ará Siria àwọn Israẹli ti wọn, wọ́n rán ìránṣẹ́. A àwọn ará Siria rékọjá odò Eufurate , pẹ̀Ṣofaki alákòóso ọmọ-ogun Hadadeseri, ó ń darí wọn.

17 Nígbà a sọ fún Dafidi nípa èyí, ó pe gbogbo Israẹli jọ wọ́n rékọjá Jordani; Ó lọ síwájú wọn, ó fa ìlà ogun dojúkọ wọ́n. Dafidi fa ìlà rẹ̀ láti àwọn ará Siria jagun wọ́n dojú ìjà kọ ́. 18 Ṣùgbọ́n àwọn ará Siria sálọ kúrò níwájú Israẹli, Dafidi pa ̀́dẹ́gbàárin (7,000) agun-kẹ̀kẹ́ wọn àti ̀kẹ́ méjì (40,000) ọmọ-ogun ẹlẹ́ṣẹ̀. Ó pa Ṣofaki alákòóso ọmọ-ogun wọn pẹ̀.

19 Nígbà àwọn ẹrú Hadadeseri i Israẹli ti borí wọn, wọ́n ṣe àlàáfíà pẹ̀Dafidi, wọ́n ń sìn abẹ́ rẹ̀.

Bẹ́̀ ni, àwọn ará Siria ìfẹ́ ríran àwọn ará Ammoni lọ́wọ́ mọ́.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também