Pular para o conteúdo
Publicidade

Joẹli 3

A orílẹ̀-èdè lẹ́jọ́

1 "ọjọ́ wọ̀n-ọn-nì, àti àkókò náà,

nígbà èmi tún ìgbèkùn Juda àti Jerusalẹmu padà bọ̀.

2 Èmi yóò gbogbo orílẹ̀-èdè jọ

pẹ̀èmi yóò wọn àfonífojì Jehoṣafati.

Èmi yóò wọn wíjọ́ níbẹ̀ nítorí àwọn ènìyàn mi,

àti nítorí Israẹli ìní mi,

wọ́n fọ́nká àárín àwọn orílẹ̀-èdè,

wọ́n pín ilẹ̀ mi.

3 Wọ́n si ti di ìbò fún àwọn ènìyàn mi;

wọ́n ti fi ọmọdékùnrin kan fún panṣágà obìnrin kan,

wọ́n ta ọmọdébìnrin kan fún ọtí wáìnì, wọ́n ó mu.

4 3.4-8: Isa 23; El 26.1–28.19; Am 1.9-10; Sk 9.3-4; El 28.20-26; Sk 9.2; Isa 14.29-31; Jr 47; El 25.15-17; Am 1.6-8; Sf 2.4-7; Sk 9.5-7. "Nísinsin yìí, ni ̀yin fi ṣe Tire àti Sidoni, àti gbogbo ̀yin ẹkún Filistia? ̀yin yóò ha sàn ̀san fún mi? ̀yin san ̀san fún mi, kánkán àti kíákíá èmi yóò san ̀san ohun ti ̀yin ṣe padà sórí ara yín. 5 Nítorí ̀yin fàdákà mi àti wúrà mi, ̀yin si ohun rere dáradára mi lọ sínú tẹmpili yín. 6 Àti àwọn ọmọ Juda, àti àwọn ọmọ Jerusalẹmu ̀yin ti fún àwọn ará Giriki, ̀yin à wọn jìnnà kúrò agbègbè ilẹ̀ ìní wọn.

7 "Kíyèsi í, èmi yóò gbé wọ́n dìde kúrò níbi ̀yin ti wọ́n , èmi yóò san ̀san ohun ti ṣe padà sórí ara yín. 8 Èmi yóò si àwọn ọmọkùnrin yín àti àwọn ọmọbìnrin yín ọwọ́ àwọn ọmọ Juda, wọ́n yóò wọ́n fún àwọn ara Sabeani, fún orílẹ̀-èdè kan ó jìnnà réré." Nítorí Olúwa o ti sọ .

9 kéde èyí àárín àwọn kèfèrí;

dira ogun,

àwọn alágbára.

Jẹ àwọn ajagun wọn bẹ̀rẹ̀ ogun.

10 3.10: Isa 2.4; Mt 4.3. fi irin ìtulẹ̀ yín rọ idà,

àti dòjé yín rọ ̀kọ̀.

Jẹ́ aláìlera ,

"Ara mi le koko."

11 kánkán, gbogbo ̀yin kèfèrí láti gbogbo àyíká,

gbá ara yín jọ káàkiri.

Níbẹ̀ o àwọn alágbára rẹ sọ̀kalẹ̀, Olúwa.

12 ", gòkè àfonífojì

Jehoṣafati ̀yin kèfèrí:

nítorí níbẹ̀ èmi yóò jókòó láti ṣe

ìdájọ́ àwọn kèfèrí káàkiri.

13 tẹ dòjé bọ̀ ́,

nítorí ìkórè pọ́n.

, sọ̀kalẹ̀,

nítorí ìfúntí kún,

nítorí àwọn ọpọ́n kún àkúnwọ́sílẹ̀,

nítorí ìwà búburú wọn pọ̀!"

14 ̀pọ̀lọpọ̀, ̀pọ̀lọpọ̀

àfonífojì ìpinnu!

Nítorí ọjọ́ Olúwa si dẹ̀dẹ̀

àfonífojì ìdájọ́.

15 Oòrùn àti òṣùpá yóò ṣú òkùnkùn,

àti àwọn ìràwọ̀ yóò tan ìmọ́lẹ̀ wọn mọ́.

16 Olúwa yóò ramúramù láti Sioni ,

yóò fọ ohùn rẹ̀ jáde láti Jerusalẹmu ;

àwọn ̀run àti ayé yóò tìtì.

Ṣùgbọ́n Olúwa yóò ṣe ààbò àwọn ènìyàn rẹ̀,

àti agbára àwọn ọmọ Israẹli.

Ìbùkún fún àwọn ènìyàn Ọlọ́run

17 "Nígbà náà ni ̀yin yóò mọ̀ , èmi ni Olúwa Ọlọ́run yín,

ń gbé Sioni òkè mímọ́ mi.

Ìgbà náà ni Jerusalẹmu yóò jẹ́ mímọ́;

àwọn àjèjì yóò o mọ́.

18 "ọjọ́ náà, àwọn òkè ńlá yóò máa kán ọtí wáìnì tuntun sílẹ̀,

àwọn òkè kéékèèké yóò máa sàn fún wàrà;

gbogbo odò Juda ó gbẹ́ yóò máa sàn fún omi.

Orísun kan yóò ṣàn jáde láti inú ilé Olúwa ,

yóò rin omi àfonífojì Ṣittimu.

19 Ṣùgbọ́n Ejibiti yóò di ahoro,

Edomu yóò di aṣálẹ̀ ahoro,

nítorí ìwà ipá a àwọn ọmọ Juda,

ilẹ̀ ẹni wọ́n ti ta ̀jẹ̀ aláìṣẹ̀ sílẹ̀.

20 Ṣùgbọ́n Juda yóò jẹ́ ibùgbé títí láé,

àti Jerusalẹmu láti ìran ìran.

21 Nítorí èmi yóò wẹ ̀bi ̀jẹ̀ wọn , èmi ì wẹ̀.

Nítorí Olúwa ń gbé Sioni."

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também

Joel
Ver todos os capítulos de Joel