Pular para o conteúdo
Publicidade

Amosi 1

1 Àwọn ̀rọ̀ Amosi, ̀kan lára àwọn olùṣọ́-àgùntàn Tekoa; ohun o nípa Israẹli ọdún méjì ṣáájú ilẹ̀-rírì, nígbà Ussiah ọba Juda àti Jeroboamu ọmọ Jehoaṣi jẹ́ ọba ilẹ̀ Israẹli.

2 1.2: Jl 3.16. Ó ,

"Olúwa yóò jáde láti Sioni,

ohùn rẹ̀ yóò sán àrá láti Jerusalẹmu ;

ibùgbé àwọn olùṣọ́-àgùntàn yóò ṣọ̀fọ̀,

orí òkè Karmeli yóò rọ."

Ìdájọ́ àwọn aládùúgbò Israẹli

3 1.3-5: Isa 17.1-3; Jr 49.23-27; Sk 9.1. Èyí ni ohun Olúwa :

"Nítorí ̀ṣẹ̀ mẹ́ta Damasku,

àní fún mẹ́rin, Èmi ìpinnu ìjìyà mi padà.

Nítorí wọn fi ohun èlò ìpakà pa Gileadi.

Pẹ̀ohun èlò irin ó eyín mímú,

4 Èmi yóò rán iná ilé Hasaeli,

èyí ti yóò àwọn ààfin Beni-Hadadi run.

5 Èmi yóò ṣẹ́ ̀ìdábùú Damasku;

Èmi yóò pa ọba ó àfonífojì Afeni run

àti ẹni ó di ̀aládé Beti-Edeni.

Àwọn ará a Aramu yóò lọ ìgbèkùn Kiri,"

ni Olúwa .

6 1.6-8: Isa 14.29-31; Jr 47; El 25.15-17; Jl 3.4-8; Sf 2.4-7; Sk 9.5-7. Èyí ni ohun Olúwa :

"Nítorí ̀ṣẹ̀ mẹ́ta Gasa,

àní nítorí mẹ́rin,

Èmi ìpinnu ìjìyà mi padà.

Gẹ́gẹ́ í oníṣòwò ẹrú,

ó gbogbo àwọn ènìyàn mi ìgbèkùn.

Ó wọ́n fún Edomu,

7 Èmi yóò rán iná ara odi Gasa

yóò gbogbo ààfin rẹ̀ run.

8 Èmi yóò àwọn olùgbé Aṣdodu kúrò,

ti ẹni ó di ̀aládé Aṣkeloni .

Èmi yóò ọwọ́ mi Ekroni

títí ìyókù Filistini yóò fi ṣègbé,"

ni Olúwa Olódùmarè .

9 1.9-10: Isa 23; El 26.1–28.19; Jl 3.4-8; Sk 9.3-4. Èyí ni ohun Olúwa :

"Nítorí ̀ṣẹ̀ mẹ́ta ti Tire

àní nítorí mẹ́rin, Èmi yóò ìpinnu ìjìyà mi padà.

Nítorí wọ́n ta gbogbo àwọn ènìyàn ó ìgbèkùn fún Edomu.

Wọn náání májẹ̀ọbàkan,

10 Èmi yóò rán iná ara odi Tire,

yóò gbogbo àwọn ààfin rẹ̀ run."

11 1.11-12: Isa 34; 63.1-6; Jr 49.7-22; El 25.12-14; 35; Od 1-9; Ml 1.2-5. Èyí ni ohun Olúwa :

"Nítorí ̀ṣẹ̀ mẹ́ta Edomu,

àní nítorí mẹ́rin, Èmi ìpinnu ìjìyà mi padà.

Nítorí òhun fi idà lépa arákùnrin rẹ̀,

Ó gbé gbogbo àánú sọnù,

ìbínú rẹ̀ ń faniya títí,

ó pa ìbínú rẹ̀ èéfín mọ́,

12 Èmi yóò rán iná orí Temani,

yóò gbogbo ààfin Bosra run."

13 1.13-15: Jr 49.1-6; El 21.28-32; 25.1-7; Sf 2.8-11. Èyí ni ohun Olúwa :

"Nítorí ̀ṣẹ̀ mẹ́ta ti Ammoni,

àní mẹ́rin, Èmi ìpinnu ìjìyà mi padà.

Nítorí wọn ti la inú àwọn aboyún Gileadi

wọ́n ba à fẹ ilẹ̀ wọn sẹ́yìn.

14 Èmi yóò rán iná ara odi Rabba

èyí yóò àwọn ààfin rẹ̀ run

pẹ̀ìhó ayọ̀ ọjọ́ ogun,

pẹ̀ìjì líle ni ọjọ́ àjà.

15 Ọba wọn yóò lọ ìgbèkùn,

òun àti àwọn ọmọ-aládé rẹ̀ lápapọ̀,"

ni Olúwa .

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também