Pular para o conteúdo
Publicidade

1 Samuẹli 29

Akiṣi rán Dafidi Siklagi

1 Àwọn Filistini gbogbo ogun wọn jọ Afeki: Israẹli ni ibi ìsun omi ó Jesreeli. 2 Àwọn ìjòyè Filistini kọjá ̀rọ̀̀rún àti lẹgbẹẹgbẹ̀rún; Dafidi àti àwọn ọmọkùnrin rẹ̀ pẹ̀Akiṣi kẹ́yìn. 3 Àwọn ìjòyè Filistini béèrè , "Kín ni àwọn Heberu ń ṣe níhìn-ín yìí?"

Akiṣi fún àwọn ìjòyè Filistini "Dafidi kọ yìí, ìránṣẹ́ Saulu ọba Israẹli, ó lọ́dọ̀ mi láti ọjọ́ wọ̀nyí tàbí láti ọdún wọ̀nyí, èmi ì í àṣìṣe kan ni ọwọ́ rẹ̀ láti ọjọ́ ó ti ̀dọ̀ mi títí di òní yìí."

4 Àwọn ìjòyè Filistini bínú i; àwọn ìjòyè Filistini fún un , "Jẹ́ ọkùnrin yìí padà ó lọ ipò rẹ̀ ó fi fún un, ó jẹ́ ó wa sọ̀kalẹ̀ lọ ogun, ó ba à jásí ̀fún wa ni ogun, kín ni òun ó fi ba olúwa rẹ̀ làjà, orí àwọn ènìyàn wọ̀nyí kọ́? 5 Ṣé èyí ni Dafidi tiwọn torí rẹ̀ gberin ara wọn nínú ijó ,

" Saulu pa ẹgbẹ̀rún rẹ̀,

Dafidi si pa ẹgbẹgbàarùn-ún tirẹ̀.’ "

6 Akiṣi pe Dafidi, ó fún un , "Olúwa ti ń bẹ láààyè, ìwọ jẹ́ olóòótọ́ àti ẹni ìwà rere lójú mi, àlọ rẹ àti ààbọ̀ rẹ pẹ̀mi ogun: nítorí èmi ko ì ri búburú kan lọ́wọ́ rẹ́ láti ọjọ́ ti ìwọ ti tọ̀ , títí o fi òní yìí ṣùgbọ́n lójú àwọn ìjòyè, ìwọ ṣe ẹni ó tọ́. 7 Ǹjẹ́ yípadà o máa lọ àlàáfíà, ìwọ ṣe àwọn Filistini nínú jẹ́."

8 Dafidi fún Akiṣi , "Kín ni èmi ṣe? Kín ni ìwọ lọ́wọ́ ìránṣẹ́ rẹ láti ọjọ́ ti èmi ti ń gbé níwájú rẹ títí di òní yìí, èmi yóò fi lọ àwọn ̀ọba ."

9 Akiṣi dáhùn, ó fún Dafidi , "Èmi mọ̀ ìwọ ṣe ẹni rere lójú mi, bi angẹli Ọlọ́run; ṣùgbọ́n àwọn ìjòyè Filistini , Òun yóò wa lọ ogun.10 Ǹjẹ́, nísinsin yìí dìde òwúrọ̀ pẹ̀àwọn ìránṣẹ́ olúwa rẹ ó , ki si dìde òwúrọ̀ nígbà ilẹ̀ mọ́ máa lọ."

11 Dafidi àti àwọn ọmọkùnrin rẹ̀ dìde òwúrọ̀ láti padà lọ ilẹ̀ àwọn Filistini. Àwọn Filistini gòkè lọ Jesreeli.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também