Pular para o conteúdo
Publicidade

1 Samuẹli 26

Dafidi da ̀Saulu lẹ́̀kejì

1 26.1-25: 1Sa 24.1-22. Nígbà náà ni àwọn ará Sifi tọ Saulu Gibeah, wọn , "Dafidi ha fi ara rẹ̀ pamọ́ níbi òkè Hakila, èyí ó níwájú Jeṣimoni?"

2 Saulu dìde ó sọ̀kalẹ̀ lọ ijù Sifi ẹgbẹ̀rún mẹ́ta (3,000) àṣàyàn ènìyàn ni Israẹli pẹ̀rẹ̀ láti Dafidi ni ijù Sifi. 3 Saulu pàgọ́ rẹ̀ ibi òkè Hakila o níwájú Jeṣimoni lójú ̀, Dafidi jókòó ni ibi ijù náà, ó Saulu ń tẹ̀òun ni ijù náà. 4 Dafidi rán ayọ́lẹ̀jáde, ó mọ nítòótọ́ Saulu ń bọ̀.

5 Dafidi dìde, ó ibi ti Saulu pàgọ́ : Dafidi ibi Saulu gbé dùbúlẹ̀ , àti Abneri ọmọ Neri, olórí ogun rẹ̀: Saulu dùbúlẹ̀ láàrín àwọn kẹ̀kẹ́, àwọn ènìyàn náà pàgọ́ wọn i .

6 Dafidi dáhùn, ó fún Ahimeleki, ̀kan nínú àwọn ọmọ Hiti, àti fún Abiṣai ọmọ Seruiah ̀gbọ́n Joabu, , "Ta ni yóò ba mi sọ̀kalẹ̀ lọ sọ́dọ̀ Saulu ni ibùdó?"

Abiṣai , "Èmi yóò ba sọ̀kalẹ̀ lọ."

7 Bẹ́̀ ni Dafidi àti Abiṣai tọ àwọn ènìyàn náà lóru: ó, Saulu dùbúlẹ̀ ó ń sùn láàrín kẹ̀kẹ́, a fi ̀kọ̀ rẹ̀ gúnlẹ̀ ni ibi tìmùtìmù rẹ̀: Abneri àti àwọn ènìyàn náà dùbúlẹ̀ i .

8 Abiṣai fún Dafidi , "Ọlọ́run ti fi ̀rẹ lọ́wọ́ lónìí: ǹjẹ́ èmi bẹ̀ ́, à jẹ́ èmi o fi ̀kọ̀ gún un mọ́lẹ̀ lẹ́̀kan, èmi yóò gun un lẹ́̀méjì."

9 Dafidi fún Abiṣai , "ṣe pa á nítorí ta ni na ọwọ́ rẹ̀ ẹni àmì òróró Olúwa ó láìjẹ̀bi?" 10 Dafidi , "Olúwa ń bẹ Olúwa yóò pa á, tàbí ọjọ́ rẹ̀ yóò yóò , tàbí òun ó sọ̀kalẹ̀ lọ ibi ìjà yóò ṣègbé níbẹ̀. 11 Olúwa jẹ́ èmi na ọwọ́ mi ẹni àmì òróró Olúwa. Ǹjẹ́ èmi bẹ̀ ́, ̀kọ̀ náà ń bẹ níbi tìmùtìmù rẹ̀, àti ìgò omi a máa lọ."

12 Dafidi ̀kọ̀ náà àti ìgò omi náà kúrò níbi tìmùtìmù Saulu: wọ́n tiwọn lọ, ẹnìkan ó i, tàbí ó mọ̀: ẹnìkan ó ; gbogbo wọn sùn; nítorí oorun èjìká láti ̀dọ̀ Olúwa ti ṣubú wọ́n.

13 Dafidi rékọjá ìhà kejì, ó dúró lórí òkè kan ó jìnnà réré; àlàfo kan láàrín méjì wọn. 14 Dafidi kọ àwọn ènìyàn náà àti Abneri ọmọ Neri , "Ìwọ dáhùn, Abneri?"

Nígbà náà ni Abneri dáhùn , "Ìwọ ta ni ń pe ọba?"

15 Dafidi fún Abneri , "Alágbára ọkùnrin kọ́ ni ìwọ ? Ta ni ó dàbí ìwọ ni Israẹli? Ǹjẹ́ èéṣe ìwọ tọ́ọba Olúwa rẹ? Nítorí ẹnìkan nínú àwọn ènìyàn náà ti wọlé láti pa ọba olúwa rẹ. 16 Nǹkan ìwọ ṣe yìí dára. Olúwa ti ń bẹ, o tọ́ ̀yin ó , nítorí ̀yin pa olúwa yín mọ́, ẹni àmì òróró Olúwa. Ǹjẹ́ wo ibi ̀kọ̀ ọba gbé , àti ìgò omi ó ti níbi tìmùtìmù rẹ̀."

17 Saulu mọ ohùn Dafidi, ó , "Ohùn rẹ ni èyí Dafidi ọmọ mi?"

Dafidi , "Ohùn mi ni, olúwa mi, ọba." 18 Òun , "Nítorí kín ni olúwa mi ṣe ń lépa ìránṣẹ́ rẹ̀? Kín ni èmi ṣe? Tàbí ìwà búburú wo ni ó lọ́wọ́ mi. 19 Ǹjẹ́ èmi bẹ̀ ́, ọba, olúwa mi, gbọ́ ̀rọ̀ ìránṣẹ́ rẹ. ó ṣe Olúwa ti sókè mi, jẹ́ òun o gba ẹbọ; ṣùgbọ́n o ṣe ọmọ ènìyàn ni, ìfibú ni wọn ó jásí níwájú Olúwa; nítorí wọn mi jáde lónìí èmi ba à ìpín nínú ilẹ̀ ìní Olúwa, , Lọ sin àwọn ọlọ́run mìíràn.20 Ǹjẹ́ ṣe jẹ́ ̀jẹ̀ mi ó sàn sílẹ̀ níwájú Olúwa; nítorí ọba Israẹli jáde láti ̀mi bi ẹni ń dọdẹ àparò lórí òkè ńlá."

21 Saulu , "Èmi ti dẹ́ṣẹ̀: yípadà, Dafidi ọmọ mi: nítorí èmi yóò wa ibi rẹ mọ́, nítorí ̀mi ti ṣe iyebíye lójú rẹ lónìí: ó, èmi ti ń hùwà òmùgọ̀, mo ti ṣìnà jọjọ."

22 Dafidi dáhùn, ó , "ó, ̀kọ̀ ọba! ó jẹ́ ̀kan nínú àwọn ọmọkùnrin rékọjá gbà á. 23 Olúwa o san án fún olúkúlùkù òdodo rẹ̀ àti òtítọ́ rẹ̀: nítorí Olúwa fi mi lọ́wọ́ lónìí, ṣùgbọ́n èmi fẹ́ nawọ́ mi ẹni àmì òróró Olúwa. 24 ó, gẹ́gẹ́ ̀rẹ ti tóbi lónìí lójú mi, bẹ́̀ ni ki ̀mi ó tóbi lójú Olúwa, ó gbà lọ́wọ́ ibi gbogbo."

25 Saulu fún Dafidi , "Alábùkún fún ni ìwọ, Dafidi ọmọ mi: nítòótọ́ ìwọ yóò ṣe nǹkan ńlá, nítòótọ́ ìwọ yóò borí."

Dafidi ̀rẹ̀ lọ, Saulu yípadà ibùgbé rẹ̀.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também