Pular para o conteúdo
Publicidade

1 Samuẹli 28

Saulu tọ Abókùúsọ̀rọ̀ lọ

1 àwọn ọjọ́ wọ̀nyí, àwọn Filistini àwọn ogun wọn jọ, láti Israẹli . Akiṣi fún Dafidi , "Mọ̀ dájúdájú , ìwọ yóò mi jáde lọ ibi ìjà, ìwọ àti àwọn ọmọkùnrin rẹ."

2 Dafidi fún Akiṣi , "Nítòótọ́ ìwọ ó mọ ohun ìránṣẹ́ rẹ ṣe."

Akiṣi fún Dafidi , "Nítorí náà ni èmi ó ṣe fi ìwọ ṣe olùṣọ́ orí mi ni gbogbo ọjọ́."

Saulu àti Abókùúsọ̀rọ̀ Endori

3 Samuẹli ti , gbogbo Israẹli sọkún rẹ̀, wọ́n sin ín Rama ìlú rẹ̀. Saulu ti àwọn abókùúsọ̀rọ̀ ọkùnrin, àti àwọn abókùúsọ̀rọ̀ obìnrin kúrò ilẹ̀ náà.

4 Àwọn Filistini ara wọn jọ, wọ́n , wọ́n Ṣunemu: Saulu gbogbo Israẹli jọ, wọ́n tẹ̀Gilboa. 5 Nígbà Saulu ogun àwọn Filistini náà òun bẹ̀, àyà rẹ̀ wárìrì gidigidi. 6 Nígbà Saulu béèrè lọ́dọ̀ Olúwa, Olúwa a lóhùn nípa àlá, nípa Urimu tàbí nípa àwọn wòlíì. 7 Saulu fún àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀ , "mi obìnrin kan ó ̀abókùúsọ̀rọ̀ èmi yóò tọ̀ ́ lọ, èmi yóò béèrè lọ́wọ́ rẹ̀!"

Àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀ fún un , "ó, obìnrin kan Endori ó ̀abókùúsọ̀rọ̀."

8 Saulu pa ara , ó aṣọ mìíràn wọ̀, ó lọ, àwọn ọmọkùnrin méjì pẹ̀rẹ̀, wọ́n ̀dọ̀ obìnrin náà lóru: òun , "Èmi bẹ̀ ́, fi ̀abókùúsọ̀rọ̀ wo nǹkan fún mi, o ẹni èmí ó dárúkọ rẹ̀ fún sókè fún mi."

9 Obìnrin náà a lóhùn , "ó, ìwọ à mọ ohun Saulu ṣe, òun ti àwọn abókùúsọ̀rọ̀ obìnrin, àti àwọn abókùúsọ̀rọ̀ ọkùnrin kúrò ilẹ̀ náà; ǹjẹ́ èéha ṣe ìwọ dẹkùn fún ̀mi, láti wọ́n pa ."

10 Saulu búra fún un nípa Olúwa , "Olúwa ti ń bẹ láààyè, ìyà kan yóò jẹ́ ́ nítorí nǹkan yìí."

11 Obìnrin náà bi í , "Ta ni ̀ó sókè fún ?"

Òun , "Samuẹli gòkè fún mi."

12 Nígbà obìnrin náà Samuẹli, ó kígbe lóhùn rara: obìnrin náà Saulu sọ̀rọ̀ , "Èéṣe ìwọ fi tàn jẹ? Nítorí Saulu ni ìwọ jẹ́."

13 Ọba fún un , "ṣe bẹ̀; kín ni ìwọ ?"

Obìnrin náà fún Saulu , "Èmi ọlọ́run kan ń ti ilẹ̀ ."

14 Ó bi í , "Báwo ni ó ti i ."

Ó , "Ọkùnrin arúgbó kan ni ó ń bọ; ó fi agbádá bora."

Saulu mọ̀ , Samuẹli ni; ó tẹríba, ó wólẹ̀.

15 Samuẹli i fún Saulu , "Èéṣe ìwọ fi ń yọ lẹ́nu láti mi sókè?"

Saulu dáhùn ó , "Ìpọ́njú ńlá mi; nítorí àwọn Filistini ń mi jagun, Ọlọ́run kọ̀ sílẹ̀, mi lóhùn mọ́, nípa ọwọ́ àwọn wòlíì, tàbí nípa àlá; nítorí náà ni èmi ṣe ́, ìwọ fi ohun èmi yóò ṣe hàn mi."

16 Samuẹli , "Ó ti ṣe ń bi léèrè nígbà ó jẹ́ , Olúwa ti kọ̀ ́ sílẹ̀, o di ̀rẹ̀. 17 Olúwa ṣe fún ara rẹ̀ gẹ́gẹ́ ó ti ti ipa ọwọ́ mi sọ: Olúwa ìjọba náà kúrò ọwọ́ rẹ̀, ó fi fún aládùúgbò rẹ́, àní Dafidi. 18 Nítorí ìwọ gbọ́ ohùn Olúwa ìwọ ṣe iṣẹ́ ìbínú rẹ̀ Amaleki nítorí náà ni Olúwa ṣe nǹkan yìí lónìí yìí. 19 Olúwa yóò fi Israẹli pẹ̀ìwọ àwọn Filistini lọ́wọ́, ̀la ni ìwọ àti àwọn ọmọ rẹ ọkùnrin yóò pẹ̀mi: Olúwa yóò fi ogun Israẹli àwọn Filistini lọ́wọ́."

20 Lójúkan náà ni Saulu ṣubú lulẹ̀ gbalaja níbí ó ṣe gùn , ̀á gidigidi nítorí ̀rọ̀ Samuẹli; agbára fún un; nítorí jẹun ọjọ́ náà tọ̀sán tòru.

21 Obìnrin náà tọ Saulu , ó i ó nínú ìbànújẹ́ púpọ̀, ó fún un , "ó, ìránṣẹ́bìnrin rẹ́ ti gbọ́ ohun rẹ̀, èmi ti fi ̀mi ọwọ́ mi, èmi ti gbọ́ ̀rọ̀ ti ìwọ sọ fún mi. 22 Ǹjẹ́, nísinsin yìí èmi bẹ̀ ́, gbọ́ ohùn ìránṣẹ́bìnrin rẹ, èmi yóò fi oúnjẹ díẹ̀ síwájú rẹ̀; jẹun, ìwọ yóò lágbára, nígbà ìwọ ń lọ lọ́."

23 Ṣùgbọ́n ó kọ̀, ó , "Èmi yóò jẹun."

Ṣùgbọ́n àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀ pẹ̀rọ̀ ́. Ó dìde kúrò ni ilẹ̀, ó jókòó lórí àkéte.

24 Obìnrin náà ni ẹgbọrọ màlúù kan ti ó sanra ni ilé, ó yára, ó pa á, ó ìyẹ̀fun, ó ó, ó fi ṣe àkàrà àìwú. 25 Ó un síwájú Saulu, àti síwájú àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀; wọ́n jẹun. Wọ́n dìde, wọ́n lọ òru náà.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também