Pular para o conteúdo
Publicidade

1 Samuẹli 19

Saulu gbìyànjú láti pa Dafidi

1 Saulu sọ fún Jonatani ọmọ rẹ̀ àti gbogbo àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀ wọ́n pa Dafidi. Ṣùgbọ́n Jonatani fẹ́ràn Dafidi púpọ̀ 2 Jonatani kìlọ̀ fún Dafidi , "Baba mi Saulu ̀láti pa ́, kíyèsi ara rẹ di òwúrọ̀ ̀la; lọ ibi ìkọ̀kọ̀, o pamọ́ ibẹ̀. 3 Èmi yóò jáde lọ láti dúró ̀dọ̀ baba mi orí pápá níbi ó . Èmi yóò sọ̀rọ̀ fún un nípa à rẹ, èmi yóò sọ ohun òun fún ."

4 Jonatani sọ̀rọ̀ rere nípa Dafidi fún Saulu baba rẹ̀, ó fún un , "ṣe jẹ́ ọba ó ṣe ohun dára fún Dafidi ìránṣẹ́ rẹ̀; nítorí ṣẹ̀ ́, ohun ó ṣe púpọ̀. 5 Ó fi ̀rẹ̀ wéwu nígbà ó pa Filistini. Olúwa ṣẹ́ ogun ńlá fún gbogbo Israẹli, ìwọ i inú rẹ dùn. Ǹjẹ́ nítorí ni ìwọ yóò ṣe dẹ́ṣẹ̀ Dafidi aláìṣẹ̀, ìwọ yóò fi pa á láìnídìí?"

6 Saulu fetísí Jonatani, ó búra báyìí, "Níwọ́n ìgbà Olúwa ti ń bẹ láààyè, a yóò pa Dafidi."

7 Nítorí náà Jonatani pe Dafidi, ó sọ gbogbo àjọsọ wọn fún un. Ó un fún Saulu, Dafidi lọ́dọ̀ Saulu gẹ́gẹ́ i ti tẹ́lẹ̀.

8 Lẹ́̀kan an i ogun tún , Dafidi jáde lọ, ó àwọn ara Filistini . Ó pa wọn pẹ̀agbára, wọ́n sálọ níwájú u rẹ̀.

9 Ṣùgbọ́n ̀búburú láti ̀dọ̀ Olúwa orí Saulu ó ti jókòó ilé e rẹ̀ pẹ̀̀kọ̀ rẹ̀ ọwọ́ rẹ̀. Dafidi ti fọn ohun èlò orin olókùn, 10 Saulu ̀láti gún un mọ́ ògiri pẹ̀̀kọ̀ rẹ̀, ṣùgbọ́n Dafidi yẹ̀ ́ sílẹ̀ gẹ́gẹ́ Saulu ti ju ̀kọ̀ náà mọ́ ara ògiri. alẹ́ ọjọ́ náà Dafidi fi ara pamọ́ dáradára.

11 Saulu rán ènìyàn ilé Dafidi láti ṣọ́ wọ́n pa á òwúrọ̀. Ṣùgbọ́n Mikali, ìyàwó Dafidi kìlọ̀ fún un , "o fún ̀rẹ alẹ́ yìí, ̀la ni a yóò pa ́." 12 Nígbà náà Mikali gbé Dafidi sọ̀kalẹ̀ ó fi aṣọ ó. 13 Mikali gbé ère ó tẹ́ e lórí ibùsùn, ó fi irun ewúrẹ́ ibi orí rẹ̀.

14 Nígbà ti Saulu rán ènìyàn láti lọ fi agbára Dafidi, Mikali , "Ó rẹ̀ ́."

15 Nígbà náà ni Saulu rán ọkùnrin náà padà láti lọ wo Dafidi ó sọ fún wọn , "wa fún mi láti orí ibùsùn rẹ̀ èmi ó le pa á." 16 Ṣùgbọ́n nígbà ọkùnrin náà wọlé, ère ni ó lórí ibùsùn àti irun ewúrẹ́ orí ère náà.

17 Saulu fún Mikali , "Èéṣe ìwọ fi tàn báyìí o jẹ́ ̀mi sálọ ó bọ́?"

Mikali sọ fún un , "Ó fún mi, Jẹ́ èmi ó lọ. Èéṣe èmi yóò fi pa ́?’ "

18 Nígbà Dafidi ti sálọ ó ti bọ́, ó lọ sọ́dọ̀ Samuẹli Rama ó sọ gbogbo ohun Saulu ti ṣe fún un. Òun àti Samuẹli lọ Naioti láti dúró níbẹ̀. 19 ̀rọ̀ tọ Saulu , "Dafidi Naioti Rama," 20 Saulu rán àwọn ènìyàn láti fi agbára Dafidi ṣùgbọ́n nígbà wọ́n ̀pọ̀ àwọn wòlíì ń sọtẹ́lẹ̀, pẹ̀Samuẹli dúró níbẹ̀ gẹ́gẹ́ olórí, ̀Ọlọ́run sórí àwọn arákùnrin Saulu àwọn náà ń sọtẹ́lẹ̀. 21 Wọ́n sọ fún Saulu nípa rẹ̀, ó rán ̀pọ̀ àwọn ènìyàn mìíràn lọ àwọn náà ń sọtẹ́lẹ̀. Saulu tún rán oníṣẹ́ lọ ìgbà kẹta, àwọn náà bẹ̀rẹ̀ sọtẹ́lẹ̀. 22 Nígbẹ̀yìn, òun fúnra rẹ̀ lọ Rama ó ibi àmù ńlá kan Seku. Ó béèrè, "Níbo ni Samuẹli àti Dafidi ?"

Wọ́n , "Wọ́n ìrékọjá Naioti Rama."

23 19.23,24: 1Sa 10.11,12. Saulu lọ Naioti ni Rama. Ṣùgbọ́n, ̀Ọlọ́run e lórí ó ń lọ lọ́, ó ń sọtẹ́lẹ̀ títí ó fi Naioti. 24 19.24: 1Sa 10.11,12.Ó bọ́ aṣọ rẹ̀, òun pẹ̀ń sọtẹ́lẹ̀ níwájú Samuẹli. Ó dùbúlẹ̀ bẹ́̀ gbogbo ọjọ́ náà àti òru. Ìdí nìyìí àwọn ènìyàn fi , "Ṣé Saulu náà lára àwọn wòlíì ni?"

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também