Pular para o conteúdo
Publicidade

1 Samuẹli 11

Saulu gba ìlú Jabesi sílẹ̀

1 Nahaṣi ará Ammoni gòkè lọ, ó ti Jabesi Gileadi, gbogbo ọkùnrin Jabesi fún Nahaṣi , "wa májẹ̀, àwa yóò máa sìn ́."

2 Ṣùgbọ́n Nahaṣi ará Ammoni fún un , "Nípa èyí ni èmi yóò fi a yín ṣe ìpinnu, nípa yíyọ gbogbo ojú ̀tún yín kúrò, èmi yóò ṣì fi yín ṣe ẹlẹ́lójú gbogbo Israẹli."

3 Àwọn àgbàgbà Jabesi fún un , "Fún wa ọjọ́ méje àwa rán oníṣẹ́ gbogbo Israẹli; àti agbègbè ẹni kankan jáde láti gbà , àwa yóò fi ara wa fún ."

4 Nígbà àwọn ìránṣẹ́ náà Gibeah ó jẹ́ ìlú Saulu, wọ́n sọ ̀rọ̀ wọ̀nyí fún àwọn ènìyàn, gbogbo wọn gbé ohùn wọn sókè, wọ́n sọkún. 5 Nígbà náà gan an ni Saulu padà láti pápá, pẹ̀màlúù rẹ̀, ó béèrè , "Kín ni ohun ó ṣẹlẹ̀ àwọn ènìyàn? Èéṣe wọ́n fi ń sọkún?" Nígbà náà ni wọ́n tún sọ fún wọn ̀rọ̀ àwọn ọkùnrin Jabesi.

6 Nígbà Saulu gbọ́ ̀rọ̀ wọn, ̀Ọlọ́run e pẹ̀agbára, inú rẹ̀ ru sókè. 7 Ó màlúù méjì, ó wọn wẹ́wẹ́, ó rán ẹyẹẹyọ gbogbo Israẹli nípa ọwọ́ àwọn ìránṣẹ́ náà, ó i kéde , "Èyí ni a ó ṣe màlúù ẹnikẹ́ni tọ Saulu àti Samuẹli lẹ́yìn." Nígbà náà ni ìbẹ̀Olúwa àwọn ènìyàn, wọ́n jáde ènìyàn kan ṣoṣo. 8 Nígbà Saulu wọn jọ Beseki, àwọn ọkùnrin Israẹli a jẹ́ ̀kẹ́ mẹ́̀́dógún (300,000), àwọn ọkùnrin Juda jẹ́ ẹgbàá mẹ́̀́dógún (30,000).

9 Wọ́n sọ fún àwọn ìránṣẹ́ ó , "Sọ fún àwọn ọkùnrin Jabesi Gileadi , àkókò oòrùn lọ́la, àwa yóò gbà yín sílẹ̀." Nígbà àwọn ìránṣẹ́ náà lọ wọ́n sọ èyí fún àwọn ọkùnrin Jabesi, inú wọn dùn. 10 Wọ́n sọ fún àwọn ará Jabesi , "Àwa yóò fi ara wa fún un yín ̀la, ̀yin ó ṣe gbogbo èyí ó tọ́ lójú yín wa."

11 ọjọ́ kejì Saulu pín àwọn ọkùnrin rẹ̀ ipa mẹ́ta, wọ́n ya wọ àgọ́ àwọn ará Ammoni ìṣọ́ òwúrọ̀, wọ́n pa wọ́n títí di ìmóoru ọjọ́. Àwọn tókù wọ́n fọ́nká, bẹ́̀ méjì wọn ibìkan.

Wọ́n fi ẹsẹ̀ Saulu múlẹ̀ ọba

12 Àwọn ènìyàn sọ fún Samuẹli , "Ta ni ó béèrè , Saulu yóò ha jẹ ọba lórí wa? àwọn ọkùnrin náà , a ó pa wọ́n."

13 Ṣùgbọ́n Saulu , "A yóò pa ẹnikẹ́ni lónìí, nítorí lónìí yìí ni Olúwa ṣiṣẹ́ ìgbàlà Israẹli."

14 Nígbà náà ni Samuẹli fún àwọn ènìyàn , ", jẹ́ a lọ Gilgali, a fi ẹsẹ̀ Saulu múlẹ̀ ọba." 15 Nítorí náà gbogbo ènìyàn lọ Gilgali, wọn fi Saulu jẹ ọba iwájú Olúwa. Níbẹ̀, ni wọn ti ẹbọ ìrẹ́pọ̀ iwájú Olúwa, Saulu àti gbogbo Israẹli ṣe àjọyọ̀ ńlá.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também