Pular para o conteúdo
Publicidade

Sekariah 9

Ìdájọ́ lórí àwọn ̀Israẹli

1 ̀rọ̀-ìmọ̀.

̀rọ̀ Olúwa kọjú ìjà Hadiraki,

Damasku ni yóò jẹ́ ibi ìsinmi rẹ̀;

nítorí ojú Olúwa ń bẹ lára ènìyàn,

àti lára gbogbo ̀Israẹli.

2 Àti Hamati pẹ̀yóò ṣe ààlà rẹ̀

Tire àti Sidoni o tilẹ̀ ṣe ọlọ́gbọ́n gidigidi.

3 Tire mọ odi líle fún ara rẹ̀,

ó fàdákà jọ eruku,

àti wúrà dáradára ẹrẹ̀ ìgboro.

4 Ṣùgbọ́n, Olúwa yóò gbogbo ohun ìní rẹ̀ lọ,

yóò pa agbára rẹ̀ run ojú Òkun,

a ó fi iná o run.

5 Aṣkeloni yóò í, yóò bẹ̀;

Gasa pẹ̀yóò í, yóò káàánú gidigidi,

àti Ekroni: nítorí ìrètí rẹ̀ yóò ṣákì í.

Gasa yóò pàdánù ọba rẹ̀,

Aṣkeloni yóò di ahoro.

6 Ọmọ àlè yóò gbé inú Aṣdodu,

Èmi yóò ìgbéraga àwọn Filistini kúrò.

7 Èmi yóò mu ̀jẹ̀ rẹ̀ kúrò ni ẹnu rẹ̀,

àti àwọn ohun èèwọ̀ kúrò láàrín eyín rẹ̀:

ṣùgbọ́n àwọn ṣẹ́yóò jẹ́ Ọlọ́run wa,

wọn yóò jẹ baálẹ̀ Juda,

àti Ekroni ni yóò Jebusi.

8 Èmi yóò ilẹ̀ mi

nítorí ogun àwọn wọ́n ń ohun wọn yóò bàjẹ́ kiri,

aninilára yóò bori wọn mọ́:

nítorí ni ìsinsin yìí ni mo fi ojú ṣọ́ wọn.

Ọba sioni ń bọ̀

9 9.9: Mt 21.5; Jh 12.15. Kún fún ayọ̀, ìwọ ọmọbìnrin Sioni,

ìhó ayọ̀, ìwọ ọmọbìnrin Jerusalẹmu.

ó, ọba rẹ ń bọ̀ sọ́dọ̀ rẹ:

òdodo ni òun, ó ìgbàlà;

ó ìrẹ̀lẹ̀, ó ń gun kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́,

àní ọmọ kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́.

10 Èmi ó gbé kẹ̀kẹ́ kúrò ni Efraimu,

àti ẹṣin ogun kúrò ni Jerusalẹmu,

a ó ṣẹ́ ọrun ogun.

Òun yóò kéde àlàáfíà àwọn kèfèrí.

Ìjọba rẹ̀ yóò gbilẹ̀ láti Òkun Òkun,

àti láti odò títí de òpin ayé.

11 tìrẹ, nítorí ̀jẹ̀ májẹ̀mi pẹ̀rẹ,

Èmi ó àwọn ìgbèkùn rẹ̀ sílẹ̀ kúrò nínú ̀gbun.

12 padà sínú odi agbára yín, ̀yin òǹdè ti o ni ìrètí:

àní lónìí yìí èmi sọ , èmi o san án fún ni ìlọ́po méjì.

13 Èmi ó fa Juda le mo ṣe fa ọrun mi le,

mo fi Efraimu kún un,

Èmi yóò gbé àwọn ọmọ rẹ ọkùnrin dìde, ìwọ Sioni,

àwọn ọmọ rẹ̀ ọkùnrin, ìwọ Giriki,

mo ṣe ́ idà alágbára.

Olúwa yóò farahàn

14 Olúwa yóò fi ara hàn orí wọn;

ọfà rẹ̀ yóò jáde lọ mọ̀nàmọ́.

Olúwa Olódùmarè yóò fọn ìpè,

Òun yóò lọ nínú atẹ́gùn ìjì gúúsù.

15 Olúwa àwọn ọmọ-ogun yóò dáàbò wọ́n;

wọn ó jẹ ni run,

wọn ó tẹ òkúta kànnàkànnà mọ́lẹ̀;

wọn ó mu ̀jẹ̀ wọn wáìnì,

wọn ó kún ọpọ́n,

wọn ó rin ṣinṣin àwọn igun pẹpẹ.

16 Olúwa Ọlọ́run wọn yóò gbà wọ́n ni ọjọ́ náà

agbo ènìyàn rẹ̀:

nítorí wọn ó dàbí àwọn òkúta adé,

a gbé sókè àmì lórí ilẹ̀ rẹ̀.

17 Nítorí oore rẹ̀ tóbi , ẹwà rẹ̀ pọ̀!

Ọkà yóò ̀dọ́mọkùnrin dárayá,

àti ọtí wáìnì tuntun yóò àwọn ̀dọ́mọbìnrin ṣe bẹ́̀ pẹ̀.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também