Pular para o conteúdo
Publicidade

Sekariah 13

Ìwẹ̀nùmọ́ kúrò nínú ẹsẹ̀

1 "ọjọ́ náà ìsun kan yóò ṣí sílẹ̀ fún ilé Dafidi àti fún àwọn ará Jerusalẹmu, láti wẹ̀ wọ́n mọ́ kúrò nínú ̀ṣẹ̀ àti àìmọ́ wọn.

2 "Yóò ṣe ọjọ́ náà ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun , ni èmi ó orúkọ àwọn òrìṣà kúrò ni ilẹ̀ náà, a yóò rántí wọn mọ́, àti pẹ̀èmi ó àwọn wòlíì èké àti àwọn ̀àìmọ́ kúrò ni ilẹ̀ náà. 3 Yóò ṣe, nígbà ẹnìkan yóò sọtẹ́lẹ̀ síbẹ̀, ni baba rẹ̀ àti ìyá rẹ̀ ó í yóò fún un , Ìwọ ki yóò , nítorí ìwọ ń sọ ̀rọ̀ èké ni orúkọ Olúwa.Àti baba rẹ̀ àti ìyá rẹ̀ o í yóò gun un ni àgúnpa nígbà ó sọtẹ́lẹ̀.

4 "Yóò ṣe ọjọ́ náà, ojú yóò àwọn wòlíì èké olúkúlùkù nítorí ìran rẹ̀, nígbà òun ba sọtẹ́lẹ̀; bẹ́̀ ni wọn yóò wọ aṣọ wòlíì onírun rẹ̀ o fi ń tan jẹ. 5 Ṣùgbọ́n òun o , Èmi í ṣe wòlíì, àgbẹ̀ ni èmi; nítorí a ti fi ṣe ìránṣẹ́ láti ìgbà èwe mi .6 Ẹnìkan ó fún un , Ọgbẹ́ kín wọ̀nyí ni ̀yìn rẹ?Òun o dáhùn , Wọ̀nyí ni ibi a ti mi ilé àwọn ̀rẹ́ mi.

A lu olùṣọ́-àgùntàn, agbo ẹran fọ́nká

7 13.7: Mt 26.31; Mk 14.27. "Dìde, ìwọ idà, Olùṣọ́-àgùntàn mi,

àti ẹni í ṣe ẹnìkejì mi,"

ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun :

"Kọlu Olùṣọ́-àgùntàn,

àwọn àgùntàn a túká:

èmi o ọwọ́ mi àwọn kéékèèké.

8 Yóò ṣe, ni gbogbo ilẹ̀," ni Olúwa ,

"a ó apá méjì nínú rẹ̀ kúrò yóò ;

ṣùgbọ́n apá kẹta yóò nínú rẹ̀.

9 Èmi ó apá kẹta náà la àárín iná,

èmi yóò yọ́ wọn a ti yọ́ fàdákà,

èmi yóò dán wọn , bi a ń dán wúrà :

wọn yóò orúkọ mi,

èmi yóò wọn lóhùn:

èmi yóò , Àwọn ènìyàn mi ni,

àwọn yóò , Olúwa ni Ọlọ́run wa.’ "

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também